BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó

Ẹnikẹ́ni tó ń lo pátákó alákọ̀ọ́lé "No parking" ń fi gbaga òfin ṣeré - Ọlọ́pàá Nàìjíríà
Ko si ẹnikẹni to l'asẹ lati gbe patako ti wọn kọ "No parking si lara" lai jẹ wi pe ọlopaa mọ sii.
Ìṣẹ́jú kan BBC
Akójọpọ̀ iroyin jákejádo agbáye laárin isẹ́ju kan
Fídíò, Akẹ́kọ̀ọ́ LASU láàrọ́ọ̀, Mọkálíìkì lọ́sàn án, ẹni tó ń ṣe bàtà lálẹ̀ ní mí- Olamide, Duration 3,41
Olaitan Olamide sọ̀rọ̀ nípa bó ṣe kọ́ iṣẹ́ títún ọkọ̀ ṣe lọ́dọ̀ọ baba rẹ, Mufutau àti ìdí tí òun fi kọ́ iṣẹ́ bàtà.
Òͅnà tí àwoͅn onísͅòwò POS ń gbà lu àwoͅn ènìyàn ní jìbìtì rèé – Onísͅòwò POS sͅàlàyé
Arakunrin naa ni awoͅn ole le lo BVN eniyan lasiko ti woͅn ba n lo POS ni oͅdoͅ woͅn, ti woͅn a si loͅ si apo isuna naa leͅyin, lati ko gbogbo owo to wa ninu apo isͅuna eͅni oͅhun.
NÍ YÀJÓYÀJÓ Àwoͅͅn adarí orílèͅèdè ní ìhà ìlà-òòrùn Afrika sͅͅèpàdé lórí rògbòdìyàn tó ń wáyé ní DR Congo
O kere tan, ọkunrin mẹwaa lo wọ ile obibrin ọhun ti oun ati ọmọ rẹ mẹrin, to fi mọ iya agba kan n gbe lati da seria fun.
Ìròyìn Pàtàkì
Mọ̀ nípa oògùn olóró Fentanyl tí àwọn kan fẹ́ má a tà ní Naijiria báyìí
Fentanyl ni oògùn tí wọ́n ni pé ó lágbára ju Tramadol àti Heroin lọ nílọ pò ọgọ́rùn ún
Amnesty International korò ojú sí ìdájọ́ ile-ẹjọ Kano lórí àwọn tó ṣe Tiktok fi fi Ganduje ṣe àwàdà
Adájọ́ pàṣẹ pé kí wọ́n lu génde méjì, kí wọ́n tún gbálẹ̀ ilé ẹjọ́ nítorí Tiktok
Fídíò, Ọkọ kejì tí mo fẹ́ ti kọ́kọ́ sọ pé kí n dá àwọn ọmọ mi padà fún bàbá wọn kó tó dáná sùn wọn- Esther, Duration 8,26
Awọn ọlọpaa ti mu Joseph Ojo lori ẹsun didana sun eeyan marun un nibi ti awọn meji ti ku bayii ninu awọn ọmọ naa.
Fídíò, Ọdùn kẹwàá ni mo tó rín, ojú ri tó ṣùgbọ́n ẹ má sọrètí nú lórí ọmọ àkàndá ẹ̀dá- Oriogbade, Duration 5,19
BBC wa adẹrinpoṣonu àkánda ẹ̀da tó jẹ́ fọga Oriogbade kan, o sọrọ lori irinajo rẹ láti kekere di asiko yii.
Mọ̀ sí i nípa ètò ìdìbò ilé ìgbìmò asòfin Amẹrika
America 2022 election: Mọ̀ sí i nípa ètò ìdìbò ilé ìgbìmò asòfin Amẹrika
Alága EFCC tó ṣe àìgbọràn sí àṣẹ ilé ẹ̀jọ́ ló yẹ́ kó lọ sí ẹ̀wọ̀n kìí ṣe Bawa - EFCC
Ileẹjọ giga niluu Abuja ti ni ki Ọga agba fun ajọ to n gbogun ti iwa ajẹbanu ni Naijiria EFCC, AbdulRasheed Bawa lọ ma gba atẹgun ni ọgba ẹwọn Kuje fun bi o ṣe kọ lati tẹle asẹ ileẹjọ
Wó ìdí tí àwọn akẹgbẹ́ Uchechi Nwachukwe ṣé ṣekúpa á ní Owerri
Awọn mọlẹbi oloogbe naa kesi awọn ọlọpaa pe ajọmọ awọn akẹgbẹ Uchechi ni lati ṣekupa nitori o ni oun kopa ninu lilu ileeṣẹ ti wọn ti sisẹ ni jibiti.
Àwoͅn awakòͅ ìgboro JIDWAN ti fagilé ìyansͅéͅlódì oͅlóͅsèͅ kan ní ìlú Eko
Eͅgbeͅ awoͅn awakoͅ nipinleͅ Eko , JIDWAN ti fagile iyansͅeͅlodi ti woͅn gunle fun oͅseͅ kan .
Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá pín aṣọ tuntun fún àwọn òṣìṣé
Ileeṣẹ ọlọpaa ti pasẹ pe ki wọn pin aṣọ tuntun , akoto ibori, asọ agbọtami, afẹfẹ tajutaju ati awọn nnkan miiran fun awọn ọlọpaa saaju ẹto idibo lọdun 2023.
Ìròyìn nípa òṣèlú Nàíjíríà
Báwo ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì 'Michael Okpara' méjì ṣé kú sínú iyàrá lójú oorun?
Ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Abia ti kede pe awọn tu bẹrẹ iwadii lori bi akẹkọọ meji latiu fasiti ohun ọgbin Michael Okpara ni Umudike ṣe gbẹmii mi ni ọna to so okunkun.
Igbákejì olórí ẹgbẹ́ Ilana Ọmọ Oodua kọ̀wé fi ipò sílẹ̀
Iroyin ni awọn afẹhọnuhan pẹlu asia Yoruba Nation ni wọn ṣe ifẹhọnuhan ni agbegbe Ado/Odo Ọta nipinlẹ Ogun ni Ọjọ Kẹrin, Oṣu Kọkanla, ọdun 2022.
̀Irìnàjò ojú irin Abuja-Kaduna yóò gbérasọ padà nínú oṣù yìí
Sambo ni ileeṣẹ eto irinna ti kọ ẹkọ nla lara ikọlu ti awọn agbesumọmi ṣe si ọna oju irin ọhun ninu oṣu Kẹta ọdun 2022, eyii to mu ki wọn wọgile irinajo oju ọna ọhun ṣaaju.
Ọkọ̀ tí kò bá ti kun ọdà àwọ ọkọ̀ akérò yóò bẹ̀rẹ̀ sí ní wọ gbaga òfin l'Eko - LASTMA
Ijọba ipinlẹ Eko ti fi ofin de awọn ọkọ akero ti wọn ko kun ni ọda to yẹ.
Hushpuppi rí ẹ̀wọ̀n ọdún mọ́kànlá he ní America fún ẹ̀sùn jìbìtì
Oriṣiriṣi awuyewuye lo tẹle bi ijọba ile Dubai ṣe fi pampẹ ofin gbẹ Hushpuppi laarin awọn ti wọn bu enu ate lu igbesi aye rẹ lori ẹrọ ayelujara ati awọn ololufẹ Hushpuppi lori ayelujara.
Adedoyin àti afurasí yókù ní àwọn kó jẹ̀bi ẹ̀sùn ípànìyàn tí iléẹjọ́ fí kàn wọn
Ile ejo ti sun igbejo na si ojo kinni at ojo keji oṣu kejila odun yii nitori bi awọn agbẹjọro ni awọn fẹ safihan awọn ẹlerii mii
Bayo Adelabu ké sí gómìnà Seyi Makinde kọ̀wé fipò sílẹ̀ nítorí ìkùnà ìjọba rẹ̀
Bayọ Adelabu ke si Gomina Ṣeyi Makinde lati kọwe fi ipo silẹ nitori ikuna ijọba rẹ.
'Inú ewu ńlá ni gbogbo àgbáyé wà báyìí lórí ọ̀rọ̀ àyípadà ojú ọjọ́'
Awọn olori orilẹ-ede n ṣe ipade lọwọ ni Egypt lori ọna abayọ si ayipada oju ọjọ
Fídíò, Tí mo bá ro ohun tí mo là kọjá lẹ́yìn ikú ọkọ mi, máà ti pa ara mi- aya Timothy Adegoke, Duration 6,04
Bolatito aya Timothy Adegoke sọ àwọn ohun ti ojú rl ti ri láàrin ọdun kan ti ọkọ rẹ di oloogbe fun BBC Yoruba.
Ọlọ́pàá mú ọkùnrin tó dáná sun ọmọ ìyàwó rẹ̀ márùn-ún ní Ondo
Ọlọ́pàá mú ọkùnrin tó dáná sun ọmọ ìyàwó rẹ̀ márùn-ún ní Ondo
Eré Ìdárayá
World Cup 22: Àwọn ọ̀nà àrà láti mú pápá ìṣeré tutù ní ìlú aṣálẹ̀
Báwo ni wọn yóò ṣe sọ ayẹ́ dẹ̀rùn fún àwọn agbábọ́ọ̀lù àti àwọn tó wá wò wọ́n láì ná ilé ayé ní nǹkan ní Qatar 2022?
Rẹfírí pín 'red card' mẹ́wàá níbi Ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ kàn lórílẹ̀ede Argentina
Agbabọọlu mẹwaa ni Refiri le jade nibi ifẹsẹwọnsẹ idije Champions Trophy to waye laarin ikọ Racing Club ati ikọ Boca Juniors lorilẹede Argentina.
Colombia fẹ̀yìn Flamingos Nàìjíríà gbolẹ̀ láti dé àṣekágba ìdíje FIFA u-17 Women's World Cup
Ireti ọpọ ọmọ Naijiria ni pe awọn Flamingoes yoo pegede ṣugbọn ọrọ ko ri bẹ.
Mọ̀ síi nípa ibi tí ọ̀rọ̀ Ronaldo dé dúró báyìí àti àwọn ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ tí yóò wáyé lálẹ́ òní
Atamatase agbawọwaju ikọ Manchester United, Cristiano Ronaldo ti darapọ mọ ikọ naa lẹyin ti akọnimọgba Erik Ten Hag palasẹ fun pe ko ma ṣe ìgbaradì fun ara rẹ.
Ìdí rèé tí Aston Villa fí jáwé lọ gbélé ẹ fún Steven Gerrard
Aston Villa juwe ile fun akọnimọọgba rẹ, Steven Gerrard, lẹyin ti ikọ agbabọọlu Fulham gbo ewuro si loju ninu idije liigi ilẹ gẹẹsi.
Òǹwòran bọ́ọ̀lù tó kú di 174, 191 ló fara gbọgbẹ́
Indonesia: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ní ìṣẹ̀lẹ̀ náà di ìjà ìgboro, ọlọ́pàá méjì wà lára àwọn tó kú, wọ́n ba ọ̀pọ̀ ọkọ̀ wa jẹ́.
Fídíò, Kíni ẹ mọ̀ nípa agbègbè Abẹ́sàn án?, Duration 1,41
Olóyè Alájàṣẹ́ ti Ajàṣẹ́ ni Republic of Benin ṣàlàyé ìtàn Oníkòyí tó bi orúkọ̀ ibẹ́ fún BBC Yorùbá.
Báwo ni o ṣe gbọ́ èdè Yorùbá sí?
Dan imọ rẹ nipa ede abinibi rẹ wo. nipa didahun ibeere wọnyii
Fídíò, N kò fẹ́ ṣiṣẹ́ aṣẹ́wó ló mú mi máa wa ọkọ̀ taxi - Obìnrin tó ń wa ọkọ̀ èrò, Duration 4,42
Princess Igbafe tun fikun pe ọpọ iṣẹ lo wa fun awọn obinrin lati se dipo ki wọn maa ta ara wọn fun ọkunrin. bii aṣẹwo
"Ọkọ mi kò ráyè wọ ojú ara mi láti já ìbálé lẹ́yìn oṣù kan ta ṣe ìgbéyàwó"
BBC Yorùbá ṣe ìwádìí nípa àìsàn Vaginismus àti ohun tí obìrin kan là kọjá lórí àìsàn náà, tí Dókítà sì bá wa sọ̀rọ̀ nípa ìtumọ̀ Vaginismus, ohun tó ń fà á àti ọ̀nà àbáyọ.
Ojútì, ìrẹ́nijẹ àti ìyà àìkàwé nídìí iṣẹ́ tíátà ti ọ̀pọ̀ òṣèré padà sí fásitì
BBC Yorùbá dé Fásitì táwọn òṣèré tíátà bíi Olaiya Igwe, Mr Latin, Imalian Boy àtàwọn míì ti kàwé gboyè, tí wọn sì ṣàlàyé ohun tó gbé wọn lọ kàwé si.
Kunle Afolayan sọ̀rọ̀ sókè nípa nípa sinimá Anikulapo
Kunle Afolayan bá BBC Yorùbá sọ̀rọ̀ nípa sinimá rẹ̀, Anikulapo tó ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde, ó ní ọdún mẹ́fà ni òun fi kọ ìtàn náà, tó sì ṣàlàyé àwọn oun tó jẹyọ nínú rẹ̀.
A kò sọ pé kí Nàíjíríà má pìn-ín, ọ̀rọ̀ wa ti di òrìṣà bó ò le gbè mí, ṣe mi bó o ṣe bá mi – Sowore
Oludije sipo aarẹ fẹgbẹ oselu African Action Congress, AAC, Omoyele Sowore bá BBC Yoruba sọrọ lori ipo ti Naijiria wa ati idi to se fẹ du ipo aarẹ.
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Oͅkòͅ òfúrufú tó jábóͅ ní Tanzania gbẹ̀mí ènìyàn 19
Ọkọ baalu kan jabọ si omi ni orilẹ-ede Tanzania
100 ọmọ ló ń kú ní Nàìjíríà láàrín wákàtí kọ̀ọ̀kan lójúmọ́- UNICEF
Kini ọna abayọ si iṣoro to n pa ọmọde ni Naijiria yii?
Àgùtàn di èrò àtímọ́lé ọlọ́pàá lẹ́yìn tó jẹ ẹja díndín lórí igbá onígbá
Awọn ọlọpaa mu agutan kan ati ọmọ rẹ meji fun ẹsun pe wọn jẹ ẹja oniṣowo kan nipinlẹ Borno
Lẹ́yìn ọdún kàn, ǹjẹ́ òtítọ́ ti faráhàn lórí ikú Timothy Adegoke?
A year after Timothy Adegoke:: Wo ibi tí ọ̀rọ̀ ìwádìí ikú Timothy Adegoke dé dúró
Ohun tí a mọ̀ rèé nípá òṣìṣẹ́ FRSC tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pe o fún aláboyún ní ìpá ní ikùn...
Iroyin to kan jale jako lori Twitter ni alaboyun naa bẹrẹ si ni da ẹjẹ lara ni lẹyin ti oṣiṣẹ FRSC naa fun ni ipa ni ikun.
A kò lé sàn owó Iṣẹ́ tí àwọn olùkọ́ Fásitì kò ṣe fún wọn- Ìjọba Àpapọ̀
ASUU strike 2022 update: Ijọba apapọ orilẹede Naijiria ti salaye ohun to sẹlẹ ti ijọba fi san idaji owo oṣu fun awọn olukọ fasiti
'Nigeria Immigration Services' ṣàlàyé ìdí mẹ́rin tí wọ́n fi da òṣìṣẹ́ 8 dúró tí wọ́n si kìlọ̀ fún àwọn 18 míràn
Iléeṣẹ tó n risi wiwọle ati jijade awọn eeyan ni Naijiria jáwé jokoo jẹ fun lara awọn oṣiṣẹ wọn lataari iwa kò tọ́ ti wọn n hu.
Tope Oladiji ní Ondo ti dèrò ilẹ̀ẹjọ lẹ́yìn tó ń dúnkookò láti ṣekúpa Bàbà rẹ pẹ̀lú àdá
Arakunrin kan, Tope Oladiji ni o ti dero ileẹjọ giga nipinlẹ Ondo fun ẹsun pe o dunkoko lati ṣekupa baba to bilọmọ, Kolawole Oladiji pẹlu ada.
Àwọn agbébọn tú àwọn ọmọdé mọ́kànlélógún sílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Katsina
Ọkunrin naa, to wa lara awọn ti ajinigbe ji ni marosẹ Eko si Ibadan lo ṣi aṣọ loju eegun ọrọ ọhun lasiko to n ṣe idupẹ ninu ṣọọṣi lori bo se ko sọwọ awọn ajinigbe.
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ọlọ́pàá fí èsì ìwádìí ikú ọmọ Davido, Ifeanyi Adeleke síta...
Ileeṣẹ ọlọpaa nipinlẹ Eko ti fi idi rẹ mulẹ pe esi abajade iwadii iku ọmọ Davido ti jade sita.
Ẹ fí àwòrán Obasanjo sí owó pépà tí ẹ fẹ́̀ ṣe àtúnṣe sí- Atiku Abubakar
Naira change: Oludije sipo aarẹ labẹ asia ẹgbẹ oṣelu PDP, Atiku Abubakar ti gba ijọba apapọ Naijiria niyanju lati fi aworan aarẹ tẹlẹri Olusegun Obasanjo si owo pepa ti wọn fẹ ṣe atunṣe si.
Àwọn ilé, ilẹ̀ Ike Ekweremadu tó lé ní 40 tí EFCC gbà tí wọ́n fẹ́ tà rèé...
Ile nla ni ilu London, USA, Dubai, ilu Eko ati Abuja wa lara awọn ohun ini to le ni Ogoji ti wọn fẹsun kan Ekeremadu pe o fi owo ilu to lu ni ponpo ko jọ.
Owó Náírà tí kò lè ra búrẹ́dì ni àwọn ọ̀ga wá fẹ́ ṣé àtúnṣe si - Adeboye
Pasitọ Enoch Adeboye ti bu ẹnu atẹlu bi baaki apapọ ati ijọba ṣe fẹ ṣatunṣe owo beba N200, N500 ati N1000.
Kí ló ń fa ìjà láàrin ọba Iragbiji àti Ẹ̀rọ̀ Àríkẹ́, gbajúmọ̀ Oníṣègùn ìbílẹ̀ l’Osun?
Orí ayélujára ló ti ń gbóná báyìí torí fídíò tí Aragbiji ti Iragbiji àti Ẹ̀rọ́ Arike gbé síta lórí aáwọ̀ ààrin wọn.
Tinubu fí MC Oluomo sínú ìgbìmọ̀ ìpolongo ìdìbò Ààrẹ
MC Oluomo ni pẹlu idunu ati ayọ ni oun fi gba iwe ipe lati jẹ ọkan lara igbimọ ti yoo sisẹ pọ pẹlu APC lati ri pe wọn ṣe aṣeyori ninu eto idibo aarẹ 2023.
Wo ọ̀pọ̀ ohun mère-mère tí wọn fi ṣìkẹ́ Ifeanyi, ọmọ Davido kó tó kú àti bó ṣe dé lórí ayélujára
Ọpọ ọmọ Orilẹede Naijiria lo bara jẹ lẹyin ti iroyin iku Ifeanyi Adeleke to jẹ ọmọ gbajugbaja olorin takasufe, David Adeleke tí ọpọ mọ si Davido ati Chioma Roland jade laye.
Ọba Yorùbá gbọdọ̀ ṣe tán láti ṣe ẹ̀sìn àbáláyé - Ààrẹ ẹgbẹ́ òníṣẹ̀ṣẹ̀ Ìpínlè Ọsun
Ọba Adedoyin ni lati ọdun mọkandinlogun ṣẹyin ni oun ti n sa ipa oun lati mu idagbasoke ba ilu Ikun Akoko.
Ṣé lóòtọ́ ni iléẹjọ́ jú Hushpuppi sẹ́wọ̀n ọdún mọ́kànlá?
Agbẹnusọ fun ọfiisi adajọ agba ilẹ United States to wa ni aarin gbungbun California, Mrozek Thom, sọ fun BBC pe idajọ ọdaran naa ko tii waye.
Ìdí rèé ti Femi Otedola ṣé fi ₦2.2bn yà ọkọ ojú omi ṣe ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún - DJ Cuppy
Florence Otedola, ti ọpọ mọ si DJ Cuppy tí ṣafihan idi baba rẹ, Femi Otedola ṣe na obitibiti owo lati ya ọkọ ojú omi fi ṣe ayẹyẹ ojọbi ọgọta ọdun laye.
Mó padà síbí ìbẹ̀rù mi- Kemi Afolabi kọminú bó ṣe padà sí Nàìjíríà
Gbajugbaja oṣerebinrin Kemi Afolabi ti kominu lori ipo to ba Orilẹede Naijiria lẹyin to pada de lati oke okun, eyi to sapejuwe gẹgẹ bii ohun ibẹru fun oun.
Pásítọ̀ Davido àti Chioma sọ̀rọ̀ síta lórí ipò tí tọkọ-taya wà
Ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria ti kede pe gbogbo igbiyanju n lọ lọwọ lati ṣewadii ohun to fa iku ọmọdekunrin olorin Davido, Ifeanyi Adeleke.
EFCC ká ọ̀pọ̀ báàgì owó Dọ́là àti Náírà mọ́ olùdíje ile aṣòfin lọ́wọ́
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọhun, Wilson Uwujaren ni ọwọ tẹ arakunrin naa to fẹ soju ijọba ibilẹ Ankpa ni ile aṣofin Kogi ni ọgbọnjọ oṣu kẹwaa.
Èdè Gẹ̀ẹ́sì tó wà lórí owó ilẹ̀ Algeria ń bí ilẹ̀ Faranse nínú
Apapọ owo ti banki agba Orilẹede Algeria gbe jade tí fa ọpọlọpọ awuyewuye, to si n bi awọn oloṣelu lorilẹede France ninu.
Ìbọn bá Olóòtú ìjọba Pakistan tẹ́lẹ̀, Imran Kahn níbi ìfẹ̀hónúhàn
Ọgbẹni Khan, to jẹ ẹni aadọrin ọdun lo lewaju iwọde naa ti wọn n ṣe lọ siluu Islamabad, to jẹ olu ilu orilẹ-ede ọhun.
Nọ́ọ́si méjì áti òṣìṣẹ́ ààbò méji dèrò iléẹjọ́ fún ẹ̀sùn gigé ẹran ìyá kàn nílé ìwòsàn
Àwọn afurasí fojú balé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn gígé ẹ̀yà ara òkú
'Àgbà ló ń ṣe Fasoranti, tó bá yá yóò ronúpìwàdà'
Adebanjo ni Fasoranti ti fi ipo adari silẹ fun oun, ti oun si ti di ipo naa mu nitori naa, ko si ọrọ ninu pe ẹlomiran si ni adari.
Màmá Davido, Veronica ni kò jẹ́ kí ọmọ mi, tó di dókítà lónìí, kú sínú ‘Swimming Pool’ lọ́dún 25 sẹ́yìn - Orangun Oke Ila
BBC Yorùbá ṣe àkójọ́pọ̀ ìtàn ayé Veronica Imade Adeleke, tíí ṣe màmá Davido tó dóòlà ẹ̀mí ọmọ ọba Orangun Oke Ila, ọba Adedokun Abolarin lọ́wọ́ ikú òjijì nínú omi ìlúwẹ̀ẹ́ lọ́dún mẹ́ẹ̀dọ́gùn sẹ́yìn.
Àkànṣe ìròyìn nípa àrùn Coronavirus àti Monkey Pox
"Ẹ̀fọn àbaàdì tó ń fa ibà ní Asia ti ń yawọ ilẹ̀ Adúláwọ̀"
Itankalẹ awọn ẹfọn abaadi yii si ni wọn lo n mu ki aayan awọn onisẹ iwadii lati palẹ wọn mọ nilẹ nira si.
O parí! Joe Biden ní Covid-19 dohun ìgbàgbé l‘Amẹ́ríkà ṣùgbọ́n...
Ikede aarẹ yii n waye tohun ti bi iye awọn to n padamu ẹmi wọn lọwọ Covid-19 ṣe n pọ si ni Amẹrika.
Ìjọba ya èèyàn 100 sọ́tọ̀ ní Ghana tórí àrùn pọ̀jẹ̀-pọ̀jẹ̀ Marburg
Isẹlẹ iba pọjẹ-pọjẹ to bẹ silẹ ni Ghana yii ni isẹlẹ keji ti yoo waye lẹyin ti Guinea, lawọn orilẹede to wa lẹkun iwọ oorun Afirika.
Ooru àmújù ń peléke si nílẹ̀ Yúróòpù, gbogbo ìlú gbóná janjan
Awọn onimọ nipa bi oju ọjọ se ri ti wa kede pe ooru pupọ yoo wa ni UK, France, Spain, Greece àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ.
WHO kéde ìkìlọ pàjáwìrì jakèjadò àgbáyé lórí ààrùn Monkey Pox
Monkeypox jẹ aarun ti kokoro aifojuri monkeypox le sokunfa rẹ.O yatọ si kokoro aifojuri smallpox sugbọn oun ko buru to arun igbona 'smallpox'.
Sri Lanka yan ààrẹ tuntun lẹ́yìn tí ààrẹ tẹ́lẹ̀ sálọ lásìkò ìwọ́de aráàlú
Aarẹ tuntun, Wickremesinghe ni yoo pari saa isejọba aarẹ tẹlẹ, Rajapaksa, eyi ti yoo wa sopin losu Kọkanla ọdun 2024.
Wo ohun tó yẹ ko mọ̀ nípa àrùn pọ̀jẹ̀-pọ̀jẹ̀ Marburg tó ń yára ṣekú pani
Ajọ eleto ilera lagbaaye, WHO ni kokoro arun Marburg ko ṣe wo loju rara nitori bi o ti maa n ṣọṣẹ.
Tea àti omi iyọ̀ ni èròjà tí orílẹ̀-èdè yìí fí n kojú ààrùn COVID-19
Bi itankalẹ aarun yi ṣe n peleke si, ileeṣẹ iroyin lorileede naa ti n rọ awọn eeyan lati lo oogun ibilẹ fi koju rẹ.
U.S. yóò máa fún àwọn ọmo Nàìjíríà kan ní físà ìwé ìrìnnà láì ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
Wo àwọn tó le jẹ ànàfàní físà ìwé ìrìnnà láì ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò naa.