BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìdí mẹ́rin rè é tí dọ́là ẹyọ̀kan ṣe di 600 naira ní Naijiria
Ohun to tun n ba awọn eniyan ninu jẹ ni pe ko si igba ti dọla gbe owo lori ti nkan ko di ọwọngogo ni ọja.
Gbọ́, Ìṣẹ́jú kan BBC, Duration 0,59
Àkójọpọ̀ ìsẹ̀lẹ̀ jákèjádò àgbáyé láàárín ìṣẹ́jú kan lórí BBC.
Èrò àwọn ọmọ Naijiria ṣọ̀tọ̀tọ̀ lórí àwọn tó pin gàrí, ṣúgà àti mílíkì níbi ayẹyẹ ìsọmọlórúkọ
Ninu fidio kan lori ikanni Instablog Naija loju opo Instagram ni awọn kan ti n pin gari, ṣuga ati miliki fun awọn eeyan to wa ba wọn ṣe ayẹyẹ.
''Àwọn adìyẹ tí mò ń sìn ni mo ń fún ní Indian Hemp mu ''
Awọn agbofinro to n koju lilo oogun oloro, NDLEA lo fi panpẹ ọba mu arakunrin naa ni inu ile rẹ, ni ipinlẹ Kaduna.
Àrùn measles ṣekúpa ọmọdé mẹ́rìnlá ní ìpínlẹ̀ Anambra
Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́sàn-án ní ààrùn náà ti tàn dé báyìí.
Ìròyìn àpapọ̀ Nàíjíríà
Mò ń rí ara mi bíi obìnrin tí kò pé nítorí mi ò lè bí ọmọ láyé - Nse Ikpe-Etim
Osẹre ori itage, Nse Ikpe-Etim, ti sọ pe aile bi ọmọ oun ti n mu ki oun ronu bii obinrin ti ko pe.
Ǹkan tí àwon omo Naijiria ń so nípa ''delegates'' tó ń dìbò fún egbé òsèlú ní yìí...
Ero awọn eniyan ṣe ọtọọtọ lori ọrọ awọn aṣoju to n dibo abẹle ni ẹgbẹ oṣelu saaju idibo gbogboogbo ni Naijiria.
Aisha Binani di obìnrin àkọ́kọ́ tó gbégbá orókè láti dupò gómìnà lọ́dún 2023
Aisha Binani rí ìbò 430 nínú 1011.
Sanwo Olu, Dapo Abiodun àti Abdulrazaq jáwé olúborí láti tẹ̀síwájú díje dupò lábẹ́ àsìá APC
Laideena pẹnu, oniruuru iṣẹlẹ awodamiẹnu lo waye lawọn ibudo idibo abẹnu naa kaakiri orilẹede Naijiria.
Àwọn olùfẹ́hónúhàn dáná sun ṣọ́ọ̀ṣì mẹ́ta àti mọ́ṣáláṣí mẹ́rin, ẹ̀mí ogún èèyàn sọnù
Wahala naa bẹrẹ lẹyin ti awọn kan ti kọkọ ṣekupa ogun Musulumi, nigba ti ogunlọgọ awọn mii si farapa nibi eto isinku kan.
Iléẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ lórí ikú Timothy Adegoke síwájú, Wo ohun tó fàá....
Wo ohun tọ ṣẹlẹ ni kikun nile ẹjọ giga ni Osogbo nibi igbẹjọ iku Timothy Adegoke.
Ìjoba ti fi èsùn ìpànìyàn kan oko Osinachi, Peter Nwachukwu
Ìjoba ti fi èsùn ìpànìyàn kan oko Osinachi, Peter Nwachukwu.
Olùdásílẹ̀ iléeṣẹ́ rédíò Agidigbo, Oriyomi Hamzat ti gba ìtúsílẹ̀
oriyọmi Hamzat ti kkọ sọ ninu fidio kan to fi sita pe nitori gbọnmọgbọmọ oun lori iku Timothy Adegoke to ku lọna to mu ifura dani nile itura Oloye Rahaman Adedoyin nilu Ile Ifẹ.
Ẹgbẹ́ òṣèlú APC Oyo sún ètò ìdìbò abẹ́nú sí òní, ìdí rèé
Oludije mẹfa lo fẹ jọ ta a tan nipinle Oyo lọsan yii.
Ohun ìbànújẹ́ ló ṣẹlẹ̀ ní Anambra, ẹ dákún mi ò fẹ́ kẹ́nikẹ́ni fi oró ya oró lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà- Buhari
Jubri ṣàlàyé bí àwọn agbébọn ṣekọ̀lù ìyàwó rẹ̀.
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ọlọ́pàá fipá mú mi láti buwọ́lu 'Statement'ti mí ò kọ̀ fúnra mi nípa ikú Timothy Adegoke-Adeniyi
Igbejo lori iku arakunrin Timothy Adegoke, akẹkọọ fasiti Obafemi Awolowo ni o tesiwaju ni loni.
Ó ṣe! ọkọ olùkọ́ tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìpànìyàn tó wáyé nílé ẹ̀kọ́ Texas dágbére fáyé
Ọdún mẹ́rìnlélógún ní àwọn tọkọtaya náà fi gbé papọ̀ tí wọ́n sì bí ọmọ mẹ́rin.
Mọ̀ síi nípa àwọn tó máa díje dupò gómìnà lábẹ́ àsíà ẹgbẹ́ PDP lẹ́yìn tí wọ́n ti yegé nínú ìdìbò abẹ́lé
Ọjọ kẹta , Oṣu Kẹfa ni gbedeke ti Ajọ to n risi eto idibo ni NaIjiria, INEC fun awọn ẹgbẹ oṣelu lati ṣe idibo abẹle wọn.
NÍ YÀJÓYÀJÓ Ó tó ọgọ́rùn-ún ẹ̀mí èèyàn tí Ukraine n pàdánù lójúmọ́ ní ìlà oòrùn - Aarẹ Zelensky
Lati ọjọ diẹ ni Russia ti n doju ogun kọ ila oorun Ukraine, lati gbakoso ibẹ
Mà á dá fijilanté sílẹ̀, òmìnira á wà fún ìjọba ìbílẹ̀ láti ná owó wọn- Oluwole Oluyede
Àwọn olùdíje ti ń ṣà[làyé ohun tí wọ́n ní fún ìpínlẹ̀ Ekiti.
Àwọn ọmọ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ bí mọ́kànlá pàdánù ẹ̀mi wọn lẹ́yìn iná tó ṣẹ́yọ
Àwọn ọmọ tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ bí mọ́kànlá pàdánù ẹ̀mi wọn lẹ́yìn iná tó ṣẹ́yọ.
Ọmọ ọdún 19 tí wọ́n sọ sí ẹ̀wọ̀n nitorí ọ̀kadà tó sọnù ti kú
Lori ẹrọ Twitter ni ibatan rẹ pẹlu ikanni @General_Oluchi ti sọ wi pe ati osu meji sẹyin ni wọn ti gbelọ si ọgba ẹwọn.
Ìjọba kéde òfin kónílé-ó-gbélé ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́sàn-án ní ìpínlẹ̀ Anambra
Lónìí ní òfin kónílé-ó gbélé náà yóò bẹ̀rẹ̀ láti aago mẹ́fà ìrọ̀lẹ́ sí aago mẹ́fà ìdájí.
Gómìnà Anambra, Àjọ CAN, Àjọ Arewa bu ẹnu àtẹ́ lu obìnrin àti àwọn ọmọ rẹ̀ tí wọ́n ṣekúpa
Arabinrin Harira Jibril to jẹ ọmọ ilu Adamawa ni awọn agbebọn ṣekupa pẹlu oyun inu rẹ ni ipinlẹ Anambra.
Ìdí tí mo fi fi ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sílẹ̀ - Peter Obi
Ninu atẹjade kan to fi sita l'Ọjọru, ni Peter Obi ti sọ ikede yii
Manchester City gba adé Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì ti 2021/ 2022
Eyi ni ife ẹyẹ Premier league ilẹ Gẹẹsi kẹrin ti Manchester City yoo maa gba laarin saa marun sẹyin.
Ta ni yóò gba ife ẹ̀yẹ Premier League ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì lónìí láàrín Manchester City àti Liverpool?
Igba akọkọ niyi laarin ọdun mẹwaa ti ifẹsẹwọnsẹ lati mọ olubori, awọn ẹgbẹ agbabọọlu mẹrin ti yoo kopa ni Champions league ati awọn ti yoo jabọ si agbami 'Relegation' yoo wọ ọjọ to kẹyin ni saa liigi kan.
Buhari yọ ikọ̀ D'Tiger, D'Tigress kúrò nídíje bọ́ọ̀lù alápẹ̀rẹ̀ lágbáyé fún ọdún méjì, ohun tó fàá nìyí
Ohun to han si BBC ni pe wọn gbe igbesẹ yii lati dena ipinnu awọn agbabọọlu apẹrẹ Naijiria lati wọde lawọn idije agbaye kan tako ajọ naa ati ijọba.
FIFA ní kí àjọ bọ́ọ̀lù ní Nàìjíríà, NFF ó san N156m owó gbà máà bínú fún Gernot Rohr
FIFA ni owo naa wa fun bi NFF ṣe gba iṣẹ lọwọ Rohr laipe ọjọ ti wọn jọ ṣadehun si.
Móríwú
Fídíò, Ẹ̀yin Obìnrin, ẹ yẹ́ wọ pátá gbígbóná kiri igboro, àwa èwe ń wò yín bí àwòkọ́ṣe- Akéwì, Duration 7,59
Oni ni ayajọ awọn ewe ni agbaye, wo bi àwọn ọmọde yii ṣe fi ijo ibile dabira.
Fídíò, Èmí kọ́ ni Uche Ayodeji tí wọ́n ni o ń pa mùsùlùmí Hausa, ẹ yé lé mi kiri- Ayodeji Rotinwa, Duration 4,24
Ayodeji Rotinwa pariwo sita pe oun ko ni Christopher Uche Ayodeji ti won ni pe o n pa Hausa musulumi.
Fídíò, Mo kọ ìwà ẹlẹ́yàmẹ́yà ló jẹ́ kí ń má a kọ ọmọ Abraka, Ebonyi, Plateau àti Benue nílé ẹ̀kọ́ mi lọ́fẹ̀ẹ́- Oba Abolarin, Duration 10,17
Oba Adedokun Abolarin da ile iwe ọfẹ silẹ fawọn akẹkọọ ti ko ni ireti ni Oke Ila Orangun nipinlẹ Osun.
Fídíò, Aṣọ ẹsikí tí mo wọ̀ ló sọ mi di ọlọ́wọ́ kan nígbà tí mo lọ lo ọludé- Toheeb, Duration 2,30
Fọga Toheeb Abiodun Olaniyan sọ bí o ṣe di àkàndá ẹ̀dá ṣùgbọ́n tó kọ̀ láti máa ṣagbe.
Fídíò, Wọ́n kò bí mí ní afọ́jú ṣùgbọ́n mo dúpẹ́ pé mo dí 'Principal high school' ìjọba- Lasisi Jasper, Duration 6,22
Ogbeni Lasisi Jasper fi itan igbesi aye rẹ ṣe iwuri fun awọn akanda ẹda pe ọjọ ọla yoo dara fun ẹni to tẹpamọṣẹ.
Fídíò, Ọmọ ìyá méjì ni a pàdánù láàrin ọjọ́ mẹ́ta, ọ̀rọ̀ Dayo nílò ìwádìí, ẹ dẹ́kun isọkúsọ- ẹbí akẹ́kọ̀ọ́ Poly, Duration 9,01
BBC wa ẹbi akẹkọọ Poly Ibadan to ku kan wọn ni pe Obi Dayo ku ni ọdun meje sẹyin, wọn ko tii le sin in nitori wọn n duro de àwọn ẹgbọn rẹ ni Oke Oya
Fídíò, Irọ́ ni pé àwọn ọmọ Sàtání ló ń kọ Fuji Gospel! Fuji níkan ni ‘beat’ tó jẹ́ àṣà wa, ‘Highlife’ kìí ṣe tiwa', Duration 6,27
Mike Abdul fèsì sí ọ̀rọ̀ àwọn olórin ẹ̀mí kan tó ní wọ́n ń ba pẹpẹ Ọlọ́run jẹ́ í wọ́n ṣe ń kọ Fuji tí wọ́n ń gbẹ́sẹ̀ ní Ṣọ́ọ̀ṣì.
Fídíò, Nígbà tí rẹ́kọ́ọ̀dù mí lókìkí kárí ayé, ẹ̀rù bà mí, mo ń ròó pé ọjọ́ ikú mi ti dé ni - Musiliu Haruna Isola, Duration 7,55
Musiliu tun tan imọlẹ si awọn ahesọ ati awuyewuye to ni ṣe pẹlu boya oun lo ni aṣẹ fun awọn orin rẹ kan to kọ tabi oun kọ.
Fídíò, Bí mo ṣe bẹ̀rẹ̀ eré Tíátà rèé tí mo tún fa ọmọ mi Samuel wọlé - Ajirebi, Duration 7,15
Agba oṣere, Oluwakayode Olasehinde ti ọpọ mọ si Pa Ajirebi tabi Pa James sọ irinajo aye rẹ fun BBC Yoruba.
Fídíò, Ìwà ẹranko làwọn ọmọ tó pa Deborah ní Sokoto hù! Tá ò bá bá wọn sọ̀rọ̀, ó burú - Òṣèré Sokoti, Duration 4,23
Gbajugbaja ati agba oṣere Yoruba ti ọpọ mọ si Sokoti Alagbede Orun fi aidunu han si bi wọn ṣe pa Deborah ni Sokoto.
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Àwọn agbébọn jí fadá ìjọ Kátólíkì méjì gbé ní Katsina
Alukoro ileeṣẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Katsina, SP Gambo Isah ṣalaye pe lootọ ni wọn ji awọn mẹrin naa gbe.
Ṣé lóòtọ́ ni Ààrẹ Buhari ti gbaṣẹ́ lọ́wọ́ gómìnà Báǹkì àpapọ̀ Nàìjíríà, Godwin Emefiele?
Gbogbo iroyin to n jade lati ileeṣẹ aarẹ orilẹ-ede Naijiria ko fi idi iroyin yii mulẹ.
Ọmọdé 19 ló pàdánù ẹ̀mí wọn nínú ìṣekúpani ní iléẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ́rẹ̀ Texas
Ileeṣẹ iroyin nilẹ Amẹrika daruko ọmọ meji ninu awọn mokandiinlogun to kun aa.
Seyi Makinde ni PDP gbade fún láti díje dupò gómìnà Oyo lẹ́ẹ̀kán síi nínú ìdìbò abẹnu yìí
Eyi ni lati yàn ẹni tí yoo gbe asia ẹgbẹ PDP nibi idibo gbogbogboo fun ipo gomina ipinle Oyo.
MC Oluomo, òpin ti débá gbígba owó orí lọ́wọ́ àwọn awakọ̀ ní Eko - Iléẹjọ́
Ẹgbẹ awọn awakọ tuntun rọ ileẹjọ ki o paṣẹ ki wọn ye fi iya jẹ awọn awakọ lọna aitọ.
ASUP ṣetán láti fi kún ìyanṣẹ́lódì - Ezeibe
Ààrẹ ASUP, Anderson Ezeibe ní nǹkan méjì péré nínú márùn-ún tí ẹgbẹ́ àwọn ń bèrè lọ́wọ́ ìjọba ni wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ṣe.
Wọ́n lẹ̀dí àpòpọ̀ mọ́ mi ni mo ṣe fìdí rẹmi níbi ètò ìdìbò abẹ́nú – Dino Melaye
Ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun ní ètò ìdìbò náà parí tí Yusuf sì fi ẹ̀yìn Dino janlẹ̀ pẹ̀lú ìbò 163 sí 99.
Lẹ́yìn idojúkọ ASUU, LAUTECH kéde pé kí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ wọlé wa parí sáà ètò ẹ̀kọ́ tó bẹ̀rẹ̀ tẹ́lẹ̀
Ile eko giga Fasiti naa ti ṣétan lati se Ipadẹ pẹlu awọn ẹgbẹ olukọ ile ẹkọ giga fasiti, ASUU lati mọ ọna abayo.
EFCC ṣàlàyé ìdí tó fi fípa wọ́lé mú Rochas Okorocha lẹ́yìn tí wọ́n rọ̀jò ìbọn nílé rẹ̀ l'Abuja
Bakan naa ni wọn fipa le awọn akọroyin kuro ni ile Sẹnetọ naa.
Wo nkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa 'BBC Yoruba Ekiti Governorship Debate' tí yóò wáyé lọ̀sẹ̀ yìí
Ọjọbọ ọsẹ yii ni BBC Yoruba yoo ṣe ipade itakurọsọ laarin awọn oludije si ipo gomina Ekiti
Gbajúmọ̀ Olórin Banky W ti rí tíkẹ̀ẹ̀tì ẹgbẹ́ òṣèlú PDP gbà láti díje dupò aṣòfin
Ẹgbẹ oselu PDP Ipinlẹ Oyo kede awọn to jawe olubori ninu eto ìdibo abele rẹ̀ nipinle Oyo.
Afurasí 4,000 la fi ṣìkùn òfin mú láàrín ọṣù márùn ún- Amotekun Ondo
Adari ikọ naa, Adetunji Adeleye lo fi ọrọ naa lede niluu Akure lasiko to n ba awọn akọroyin sọrọ.
Ta ni Anamekwe Nwabuoku tí ìjọba yàn láti delé sí ipò olùṣirò owó àgbà ní Nàìjíríà (AGF)?
Ni ọsẹ to kọja ni ajọ to n gbogun ti iwa ijẹkujẹ lorilẹede Naijiria, EFCC fi panpẹ ofin gbe oluṣiro owo agba lorilẹede Naijiria fun ẹsun kiko owo to to ọgọrin biliọnu naira jẹ.
Wo ohun tó yẹ kóò mọ̀ nípa aàrùn 'Monkeypox' tó gbòde kàn ní àgbáyé
Wo ohun tó yẹ kóò mọ̀ nípa aàrùn 'Monkeypox' tó gbọde kàn ní àgbáyé.
Àwọn ọmọ bíbí Arewa ní àwọn ọlọ́kada láti orílẹ̀-èdè míràn ló ń dáràn nípínlẹ̀ Eko
Ẹgbẹ awọn ọmọ ẹkun ariwa orilẹede Naijiria, Arewa Comunity ni ipinlẹ Eko ni awọn fọwọ si aṣẹ ijọba Eko lati palẹ awọn ọlọkada mọ lawọn ijọba ibilẹ kan.
A kò ní sinmi títí tí àlááfíà yóò fi padà sí Naìjíríà- Buhari
Muhammadu Buhari ṣèlérí ètò amáyédẹrùn fún àwọn ọmọ ogun, àti láti pèsè ètò aàbò tó péye.
Àwọn Jàǹdùkú kọlù alága àjọ tó ń ṣètò eré ìdárayá ní ìpínlẹ̀ Oyo
Honerebu Gbenga Adewusi lo fi ara gbọgbẹ nibi ikolu awọn janduku leyin ifẹsẹwọnsẹ to waye ni Adamasingba.
Ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn Aiye méjìdínlógún kò sí pámpẹ́ ọlópàá Ekiti lórí ikú èèyàn méjì
Ileesẹ ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti t i kéde pe awọn ti ribi mu awọn ọmọ ẹgbẹ okunkun mejidinlogun ni ipinlẹ naa.
Taliban gbé òfin kalẹ̀ lórí àwọn Obìnrin atọ́kùn ètò, bó ojú rẹ tóo bá fẹ́ ka ìròyìn bí bẹ́ẹ̀ kọ́.....
Ka nípa òfin tuntun Taliban tó ní atọ́kùn amóunmáwòrán obìnrin gbọdọ̀ bójú ká ìròyìn.
'Panel Beater' méjì ya odi òjijì lẹ́yìn tí alága ẹgbẹ́ mọkáláìkì tẹ́lẹ̀ gbá wọn l'étí ní Eko
Ija ilẹ da wahala silẹ laarin awọn ọmọ ẹgbẹ mọkalliki nipinlẹ Eko
Àkànṣe ìròyìn nípa àrùn Coronavirus
Tea àti omi iyọ̀ ni èròjà tí orílẹ̀-èdè yìí fí n kojú ààrùn COVID-19
Bi itankalẹ aarun yi ṣe n peleke si, ileeṣẹ iroyin lorileede naa ti n rọ awọn eeyan lati lo oogun ibilẹ fi koju rẹ.
Lóòtọ́ abẹ́rẹ́ Covid-19 lée jẹ́ ṣẹ̀ṣẹ̀dé ayé, àmọ́ ẹ wo ìdí tí kò lè ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ lára yín - Dókíta
Pẹlu oniruuru ibẹru ti awọn eeyan n ni si abẹrẹ Covid-19, bi yoo ba ṣiṣẹ-kiṣẹ, ẹ wo asiko ti yóò dahun lara yin.
U.S. yóò máa fún àwọn ọmo Nàìjíríà kan ní físà ìwé ìrìnnà láì ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò
Wo àwọn tó le jẹ ànàfàní físà ìwé ìrìnnà láì ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò naa.
Àwọn nǹkan mẹ́ta tí a kò tíì mọ̀ nípa Covid-19 lẹ́yìn tí àrùn náà bẹ́ sílẹ̀ rèé
Lati ọdun 2019, ko din ni miliọnu lọna ọọdunrun ati aadọta eeyan to ri fara kasa arun naa kaakiri agbaye.
Ìjọba Nàìjíríà kéde ìlànà tuntun lórí COVID-19, Ó mú àdínkù bá ìye èèyàn tó lè wọ ṣọ́ọ̀ṣì, mọ́sáláṣí
Igbimọ tẹẹkoto ti aarẹ gbe kalẹ naa ni orilẹede Naijiria ti ko wọ inu ọwọ kẹrin ọwọja kokoro arun COVID-19
Èèyàn mẹ́ta míì tún ti lùgbàdì ẹ̀dà COVID-19 tuntun Omicron ní Nàìjíríà
Naijiria ni orile-ede Afrika ti eeyan pọju nibe ti awọn eeyan ilẹ naa di fẹ wọ igba mílíọ̀nù.
'Omicron ti wọ Nàìjíríà o', ìjọba àpapọ̀ kéde; Canada bẹ́gi dínà àwọn ọmọ Nàìjíríà tó bá fẹ́ wọlé
Orilẹede Canada ni awọn ti ni ẹni meji to wọle lati orilẹede Naijiria pẹlu arun Covid-19 Omicron Variant.
Ṣé o mọ̀ pé o leè kó Covid pẹ̀lú ọmọ ìka ẹ̀sẹ̀ rẹ̀ láì mọ̀?
Ẹgbẹ awọn dokita onimọ nipa awọ ara nilẹ Britain ni akọsilẹ oniruuru aisan ara to lee ni ṣe pẹlu Covid.
Okòòwò márùn ún tí o lè bẹ̀rẹ̀ nínú ilé rẹ̀
Eniyan nilo ounjẹ lati lee dagba ki o si wa laye.
Ẹ̀dà Delta Variant COVID-19 ń gbèrú síi ní Nàìjíríà, ìjọba àpapọ̀ ra abẹ́rẹ́ àjẹsára 176,000
Nnkan bii ọgọsan ẹgbẹrun eeyan lo ti ko arun naa, ti ẹgbẹrun meji ati igba o din marun un eeyan si ti ti ara rẹ ku.