Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
Adebisi Idikan: Òun ló gba Ìbàdàn sílẹ̀ lọ́wọ́ ìyà owó orí sísan
Asamọ to wọpọ nilu Ibadan ni pe "N o kọle mi bii ile Adebisi, esu aini kọ ile kankan niyẹ."
Itumọ rẹ ni pe, ile Adebisi to wa ni Idikan nilu Ibadan jẹ ile to gbajumọ, to tobi pupọ, to si ni ọgọrun-un yara, eyi ti ẹnikan ti ko ni owo nla lọwọ, ko lee dasa pe oun fẹ kọ rara.
- Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn
- Kí ló fà ogun Ìjàyè àti ìṣubú Kurunmi, ìfẹ́ ìlú ni àbí orí kunkun?
- Duro Ladipọ, ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà àti ọmọ àlúfà tí kò gbàgbé àṣà ìbílẹ̀
- Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko
- Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus
- Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tí kìí ṣe ọmọ káàárọ̀ oòjíire
- Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
Ọmọwe Busari Adebisi, tii se arole fun idile Sanusi Adebisi ni Idikan n‘Ibadan salaye, lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ pe, eeyan kii sunkun wọ ile Adebisi, ko ma ba ẹrin jade.
O fi kun pe, baba oun lo tun ja fun ilu Ibadan, ti ọba wọn fi kuro ni Baalẹ lasan, to si di ọba alade, ti wọn n pe ni Olubadan ni oni.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Inú mi máa ń dùn láti kọrin fún àbúrò mi - Josh Posh
- Obìnrin awakọ̀ Bàálù àkọ́kọ́ láti Ọffa rèé
- 'Èmi ò kí ń ṣe ọkọ torí mi ò kí ń ṣe ojúṣe mi'
- 'Ìjákulẹ̀ ọkùnrin ló sọ mí di alárinà'
- Agbára ṣì wà lọ́wọ́ Boris Johnson bo tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀ n fi iṣẹ́ sílẹ̀
- Òògùn ìbílẹ̀ nílò ìrànwọ́ owó láti gbèrú síi, àjọ NAFDAC ké gbàjarè