Senator Elisha Abbo: Adájọ́ ní ọlọ́pàá kò fi ẹ̀rí tó dájú múlẹ̀ lórí ẹ̀ṣùn ìfìyàjẹni

Oríṣun àwòrán, @ElishaCliff
Ileẹjọ majisireti kan to kalk silu Abuja ti wọgile ẹsun ifiyajẹni ti wọn fi kan Sẹnatọ Elisha Sanbo lati ipinlk Adamawa.
Ileẹjọ ni awọn ọlọpa ko sisẹ wọn bii isẹ lori ẹjọ, nitori naa ko lẹsẹ nlẹ.
Idajọ naa si lo kọ amọ Naijiria lominu, paapaa nitori fidio kan to lu ayelujara pa lori bi Sẹnatọ Abbo se fiya jẹ obinrin ontaja kan, OsimibibraWarmate.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Kí ló mú Olorì Badrat Ajoke kúrò ní ààfin Oyo lọ́jọ́ Iléyá?
- Èlé orí owóyàá China rọjú la ṣe fẹ́ gbà á - Ìjọba àpapọ̀
- Ẹjọ́ ìfìyàjẹni dojú dé! Iléẹjọ́ ní Elijah Abbo kò lẹ́jọ́ jẹ́
- N kò ri ipa ẹ̀jẹ̀ lára ọmọ mi tó kú sí iléeṣẹ́ ọṣẹ, èjò lọ́wọ́ nínú - Òbí àkẹ́kọ̀ọ́ UI
- Mò máa ń fọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ ìyá mi, ni ìṣe àwọn obìnrin fi wù mí - Bobrisky
- Àlàyé rèé lóríi àjọṣepọ̀ tó wà láàrin èmi àti MC Oluomo - Ronke Oshodi Oke
- Ẹ bá mi wá nọ́ńbà ìpè òbí ọmọ Mummy Calm Down jáde - Yinka Ayefele
- Ọlọ́pàá sálọ fún aráàlú l‘Okeho, nígbà tí wọn yari láti ṣun olè méjì tó kù
Nibi ipade akọroyin to si tẹle isẹlẹ naa ni Sẹnatọ ọhun ti tọrọ aforijin pupọ lọwọ obinrin to fiya jẹ naa.
Nigba to n gbe idajọ ọhun kalẹ, Adajọ Abdullahi Ilelah ni oun gba ẹbẹ Abbo to ni oun ko lẹjọ jẹ lori awọn ẹsun ti wọn fi kan.
Adajọ Ilelah tun fikun pe ọlọpa lo kuna lati fi idi ẹri to giriki mulẹ pe lootọ ni Abbo fiya jẹ Warmate.
Bẹẹ ba gbagbe, ọjọ Kọkanla osu Karun ọdun 2019 ni isẹlẹ naa waye nigba ti fidio kan gba ori ayelujara kan.
Owu Water Fall: Ọba Oyewole ni ibùdó ìrìn àjò afẹ́ gidi ni àmọ́ ọ̀nà ibẹ̀ burú jáì
Fidio ọhun si lo safihan bi Abbo se n rọjo igbaju lu obinrin kan nile itaja nilu Abuja.
Isẹlẹ naa si way laarin osu mẹta ti wọn dibo yan Abbo sile asofin agba ilẹ wa, to si se ibura wọle lọjọ Kọkanla osu Kẹfa.
Ilé ẹjọ́ sún ìgbẹ́jọ́ Sẹ́nétọ̀ Elisha Abbo tó lu obìrin
Ile ẹjọ Majisireeti kan niluu Abuja ti sun ẹjọ Sẹnetọ Elisha Abbo ti wọn fi ẹsun kan pe o lu obinrin nile itaja nkan iṣere ibalopọ siwaju di ogunjọ oṣu kẹjọ ọdun yii.
Akroyin BBC jabọ pe idi ti wọn fi tun sun un siwaju ni lati jẹ ki awọn ọlọpaa le pese gbogbo aridaju ti wọn nilo fun idajọ naa.
Lori ẹsun lilu eeyan lọna aitọ pẹlu aridaju ni wọn fi gbe sẹnetọ Elisha lọ siwaju ile ẹjọ.
ile iṣẹ ọlọpaa Naijiria lo bẹrẹ ipẹjọ yii lori sẹnetọ to n ṣoju ẹkun ariwa ipinlẹ Adamawa lẹyin ti fọnran kan jade to safihan bi o ti n lu obinrin kan ni ile itaja nkan iṣere ibalopọ lAbuja.
Bi o tilẹ jẹ pe sẹnetọ naa ti tọrọ aforiji fun iwa rẹ, awọn ọmọ Naijiria ni afi ki wọn fi jofin.
Abbo tọrọ aforojin yii pẹlu ikaanu nla, lasiko ipade akọroyin to se ni olu ile ẹgbẹ PDP to wa nilu Abuja.
Awọn Iroyin mii ti ẹ le nifẹ si
- Barrister ló sọ mí di èèyàn ńlá - Ayinla Kollington
- Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
- Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́...’ rèé
- Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ
- Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
- Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin