Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ
Amotekun: Fatomilola ní gaga ọwọ̀ làwọn baba wa fi ń ṣọ́ ilé, òyìnbó ló sọ wá di ọ̀lẹ
Ilumọọka agba osere tiata kan, Peter Fatomilola ti fọwọ gbaya pe agbekalẹ ikọ alaabo Amotekun yaayi lasiko yii tori agbara oogun lawọn baba wa fi n daabo bo ara wọn laye atijọ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Fatomilola ni awọn baba wa kii se ilẹkun si ẹnu ọna ile, amọ gaga ọwọ mẹẹdogun ti to lati koju ole.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Àwọn mùsùlùmi sèèsì sin òkú Kristẹni lọ́jọ́ kejì tó kú láìmọ̀
- Ọ̀rọ̀ owó lo da emi àti Saheed Balogun pọ ti mo fi ke gbajare lori Instagram-Sotayogaga
- Ààbò Naijiria tó dojúrú, ẹ gbé ọ̀rọ̀ ọlọ́pàá abẹ́lé wò bóyá yóò san wá - Ilé aṣojú-ṣòfin
- Ẹ̀mí 15 bọ́, èèyàn 38 farapa nígbà tí ọkọ̀ akẹ́rù kan bọ́ sínú odò Ogun
- Malami, IGP àti alága APC Oyo ni yóò káwọ pọ̀'yìn rojọ nítori àwọn alaga Kansu tẹlẹri
O fikun pe igba tawọn oyinbo de ni awọn sọja ati ọlọpa de, ti a ko si lee fi ilana ibilẹ daabo bo ara wa mọ, ta wa di ọdẹ ati ọlẹ.