Oba Adedokun Abolarin ti Oke Ila: Ó ya ọ̀pọ̀ tó súnmọ́ mi lẹ́nu bí mo ṣe ń kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ pẹ̀lú ipò Ọba
Oba Adedokun Omoniyi Abolarin Aroyinkeye 1, Orangun Oke Ila sọrọ ilẹ kun!
Òrí ló yan iṣẹ́ olùkọ́ fún mi ni ń kò ṣe jẹ́ kí Ọba ti mo jẹ́ dí mi lọ́wọ́- Kabiesi Abolarin Oke Ila
Kabiesi ṣalaye idi ti o fi da ileẹ̀kọ́ Abolarin silẹ ni Oke Ila fun awọn ọmọ alaini lawujọ.
O ni awọn akẹkọọ to ku diẹ kaato fun ni ile ẹ̀kọ́ naa wa fun.
- A ti yọwọ́ olùdíje méji kúrò láwo lẹ̀yìn àyẹ̀wò, wọn kò lè díje lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ PDP- David Mark
- Kí lo mọ̀ nípa ìgbeyàwó Àbẹ̀ẹ́lẹ̀, Àṣàǹte, Ọkọ Káalẹ́ àti Gbàmí o ràmí?
- Báyìí ni Egúngún àti Orò ṣe jọ bí Ẹ̀ṣà Egúngún nílẹ̀ Yorùba
- Mo sọ kẹ̀kẹ́ mi dí ọ́kadà pẹ̀lú N35, 0000 tí mó ná sìí- Adewole ọmọ ọdún 16
- Àjákálẹ̀ àrùn tuntun tí ayé ń sọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀ rèé...
- Tí mo ba ti múra bí ọkùnrin fi kọrin, kò sí ọ̀dọ̀ ààrẹ́ tí mi ò lè wọ̀- Erelu, ọmọ Elemure Ogunyemi
Kini Kabiesi tun sọ fun BBC?
Kabiesi ni iṣẹ olukọ ni oun ti n ṣe ni eyi ti oun ko le yipada lẹyin ti o di Ọba ati pe pataki ipo Ọba ni lati mu ayipada rere ba awujọ ti eeyan n dari.
Awọn to ku diẹ kaa to fun ni aayo mi ni ọrọ Oba Abolarin.
Ati pe Kabiesi funrarẹ n kọ awọn ọmọ ni iṣẹ eto ijọba ti a n pe ni 'Government' ni eyi ti wọn si n ṣe daadaa.
Oba Adedokun Omoniyi ni ọja ọla Naijiria lo jẹ oun logun ati mimu ayipada
BBC Yoruba ba ninu awọn akẹkọọ ile iwe ọfẹ Kabiesi sọrọ nipa iriri wọn.
- Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ tí o bá fẹ́ lọ fún ìsinmi lẹ́yìn Covid 19
- EFCC ká Rochas Okorocha mọ́lé, wọ́n ní kó sẹ́bí rẹ̀ tí yóò jáde bí àwọn kò bá mú u
- Wo bi wọ́n ṣe n ṣe àmójútó ilé ìjọsìn Prophet Israel Oladele, CCC Genesis Global
- Bàbá mi ni 'Welder' Uncle mi ní 'Coiler' ṣùgbọ́n mo padà fi ṣoríire- Afusat Adeniyi
- Ta ni Anamekwe Nwabuoku tí ìjọba yàn láti delé sí ipò olùṣirò owó àgbà ní Nàìjíríà (AGF)?
- Gbajúmọ̀ Olórin Banky W ti rí tíkẹ̀ẹ̀tì ẹgbẹ́ òṣèlú PDP gbà láti díje dupò aṣòfin
Kini awọn akẹkọọ ikeji Orisa sọ?
Adeola Stella Oluwafeyisola ati Tijani Yusuuf salaye bi awọn ṣe jẹ omo orukan ṣugbọn ti Kabiesi ti fun wọn ni ireti tuntun.
Kabiesi parọwa fun awọn eeyan pe ki onikaluku ṣe ohun to yẹ fun awọn alaini to wa nitosi rẹ.
O mẹnuba awọn akẹkoo ọmọ Abraka, ọmọ ebonyi, ọmọ Benue ati Plateau to jẹ anafani ẹkọ ọfẹ ni Oke Ila Orangun ni eyi to fihan pe ko yẹ ki a ni ẹlẹyamẹya.
- Buhari lo fi kún ìṣòro Nàìjíríà ní ìlọ́po méjì, o ba ilẹ̀ jẹ́ gidi- Ojọ̀gbọ́n Banji Akitoye
- Wo bí wọ́n ṣe ń dárò Aláàfin Adeyemi ní Oyo pẹ̀lú ẹwà èdè lóríṣiríṣi
- 'Wàláhì láàrín ọdún kan péré tí mo bá dé Aso Rock, ẹ wo ǹkan tí yóò yí bírí ní Nàìjíríà'
- Mo rí ìpèníjà lórí eré oníjó láti ọ̀dọ̀ Krìsítẹ́nì aláṣọ funfun àti àwọn Mùsùlùmí - Alfa Sule
- Wo nkan tó sọ Woli ìjọ Genesis Global di ọmọ ìjọ Cele lẹ́yìn tó kúró nínú ìjọ C.A.C.