Ìtanijí lórí BBC Yorùbá, Oluwo Jogbodo: Odú Iwori Obara bá wa sọ̀rọ̀ lórí ìfaradà tó pọ̀
Ìtanijí lórí BBC Yorùbá, Oluwo Jogbodo: Odú Iwori Obara bá wa sọ̀rọ̀ lórí ìfaradà tó pọ̀
Oluwo Jogbodo- Eto Itaniji lori BBC Yoruba.
Oluwori ni ẹda itan to jẹ ọdọ ninu ẹsẹ Ifa yii ni nkan ṣẹlẹ si.
Oun ni Ifa lo lati fi parọwa kikun lori Ifarada gẹgẹ bii ọkan lara iwa omoluwabi ni ilẹ Yoruba.
Aini ati iṣẹ́ ati òṣì n ba Oluwori finra pupọ.
Lẹyin ọpọlọpọ ironu lo tọ Babalawo lọ lati lọ bi ilẹ leere.
Ifa ni ko jẹ oye Makanjuọla, ko dẹ tun rubọ pẹlu ifarada.
- Agbọ́nmágbọ́ntán, Agọ̀mágọ̀jù, mọ̀ síi nípa àwọn orúkọ Ìjàpá nínú alọ àpagbè Yorùbá
- Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko ti f'òfin de ìpéjọpọ̀ tó bá ju àádọ́ta (50) èèyàn lọ torí ọwọ́jà kejì coronavirus
- Ǹkan tÍ Sunday Igboho ṣe ní Ibarapa tún ti ṣelẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun- Olórí Miyetti Allah ilẹ̀ Yorùbá
- Mínísítà ètò ìròyìn nígbà kan rí Tony Momoh dágbére fáyé lẹ́ni ọdún mọ́kànlélọ́gọ́rin
- Ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ ní pé wọ́n pa ọmọ ogun mẹ́fà tó jẹ́ iran Igbo nikọ̀kọ̀ ní Abuja- Iléeṣẹ́ ológun
- Ilẹ̀ Amerika ń wá olùkọ́ èdè Yorùbá, wo bí o ti lè forúkọ sílẹ̀ níbí
Wo bi Olodumare ṣe gba ọna ara yanju iṣoro ọdọ to ni ifarada ko to di ọlọla.
Oluwo jogbodo rọ awọn ọdọ asiko yii lati ni igbiyanju, ki wọn tẹpa mọṣẹ.
O ni ifarada lo ku lati ni ọjọ ọla to dara fun eni ti kii ṣe ọlẹ to.
Oríṣun àwòrán, others
- Seyi Makinde fi ọkọ̀ ńlá mẹ́rin dá ikọ̀ Amotẹkun lọ́lá nípìnlẹ̀ Oyo
- Ọmọ ọdúnmẹ́tàdínlógún káwọ́ sẹ́yìn rojọ́ lórí ẹ̀sùn ìdúnkookò láti gbẹ̀mí ìyá rẹ̀''
- Ìjọba Nàìjíríà ti sún ọjọ́ ìforúkọsílẹ káàdi ìbánisọ̀rọ̀ síwájú síi
- Ọ̀rọ̀ ìfẹ́ mú àgùnbánirọ̀ di èrò iléẹjọ́ ní ìpínlẹ̀ Kogi
- Mọ̀ síi nípa Aung Suu Kyi tí wọ́n sọ sẹ́wọ̀n ní Myanmar àti bí ìgbàjọba ṣe wáyé níbẹ̀