Osun at 30: Gomina Adegboyega Oyetola ni ọbẹ̀ ìpínlẹ̀ Osun ti di àtúnse lẹ́yìn ọgbọ́n ọdún ti a dá a sílẹ̀

Oríṣun àwòrán, @Osun
Lọdun 1991 ni aarẹ Naijiria nigba kan ri, Ibrahim Badamosi Babangida da a sile pẹlu a\won ipinlẹ mii bi Enugu.
Lati ara ipinlẹ Oyo ni wọn ti yọ Osun kuro ti wọn si sọọ ni orukọ odo Osun Osogbo pẹlu ilu Osogbo gẹgẹ bii olu ilu rẹ.
Leyin ọgbọn ọdun yii ni Gomina Adegboyega Oyetola to n tukọ rẹ lasiko yii ni pe iyan rẹ ti di ti atungun bayii.
- Ìṣẹ̀lẹ̀ omíyalé yóò wáyé ní Eko, Oyo, Ogun, Ondo àti ìpínlẹ̀ 30 míì láàrín ọjọ́ mẹ́ta- NiMet
- Wo ẹ̀sùn ìwà ọ̀daràn márùn ún tí àwọn èèyàn ilú Eko fi kan àwọn òṣìṣẹ́ LASTMA
- Wo ìdájọ́ tí ilé ẹjọ́ fún àgbà nọ́ọ̀sì tó ta ọmọ ọdún mẹ́fà ní N200,000
- Ṣé lóòtọ́ ni pé ilé ẹjọ́ sọ pé kí Lizzy Anjorin san 9.5m fún ẹni tó pé lẹ́jọ́ nítorí ọ̀rọ̀ ọkọ rẹ̀?
- Ogúnlọ́gọ̀ àwọn dókítà bẹr̀ẹ̀ ètò ìgbanisíṣẹ́ l'Abuja lọ́nà àti sálọ sí Saudi Arabia
- Ìkọlù tó wáyé ní ilé ẹ̀kọ́ ológun ní Kaduna le jẹ́ ète láti fi ìjọba Buhari ṣe ẹlẹ́yà - Garba Shehu
Oyetola ni ọkan lara ohun tuntun lati ṣe ni lati sọ ipinlẹ naa di ti eyi to n pese iṣẹ yatọ si iṣẹ ijọab nikan ti a mọ wọn mọ.
Oyetola sọ eyi lasiko to n ba awọn akoroyin sọrọ lori eto olosoosu nile iṣẹ iroyin OSBC ti ipinlẹ Osun.
O ni ijọba ti n mu ayipada de ba okowo ati iṣẹ pipese sii.
Rape survivor: Ìyá mi ni ń kò gbọdọ̀ sọ̀rs kí ilé má bà á dàrú- Oluwatobi Raji