Okunrounmu on Buhari's government: Kò jọ pé àwọn èèyàn ń ṣa oúnjẹ jẹ lórí àkìtàn jẹ ní ìjọba rẹ
Okunrounmu on Buhari's government: Kò jọ pé àwọn èèyàn ń ṣa oúnjẹ jẹ lórí àkìtàn jẹ ní ìjọba rẹ
Sẹnetọ orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, Femi Okunrounmu ti sọ wipe ijiya Ọlọrun ni ijọba Buhari jẹ fun ọmọ Naijiria ati wipe Buhari ko mọ nkankan nipa eto ọrọ aje.
O ba BBC Yoruba sọrọ lori ipo ti Naijiria wa lonii pẹlu gbogbo ohun ti orilẹede naa n kọju o si gbee lẹgbẹ kẹgbẹẹ awọn ileri ti aarẹ Muhammadu Buhari ṣe fun awọn ọmọ Naijiria nigba ti wọn dibo yan an wọle.
Awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si:
"Láti ọjọ tí Nàìjíríà tí ń ní ìjọba, mi ò rí èyí tó burú tó ti Buhari rí. Kò jọ pé àwọn èèyàn ń ṣa oúnjẹ jẹ lórí àkìtàn bó tilẹ̀ jẹ́ pé ebi ń pa àwọn èèyàn gan lágbàáyé".
O ni olè ni gbogbo àwọn sẹ́nétọ̀ ń jà l'Abuja báyii.
Alagba Okunrounmu ni ṣe ni eto ọrọ aje wa n buru sii ti aarẹ to wa lori oye ko si mọ nkankan nipa ọrọ aje rara.
- Wo ohun tí àwọn ọba Yorùbá l'órílẹ̀èdè Benin Republic fẹ́ gbé ní ìgbésẹ̀ nítorí Sunday Igboho
- 'Ó sàn fún wa kí Sunday Igboho kú sí Cotonou ju kí wọ́n dáa padà sí Nàìjíríà lọ'
- Isó fààá leè jẹ́ kí ẹ kò Covid-19 níbi tí o ba fún pọ̀! Ẹ fura o!
- Pẹ̀lú omijé lójú làwọn òbí akẹ́kọ̀ọ́ 28 Bethel Baptist táwọn ajínigbé tú sílẹ̀ fi pàdé ọmọ wọn
- 'Bàbá tó gbé owó ''ransom'' lọ fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jígbé, àwọn jàndùkù ajínigbé bá mú òun náà mọ́lẹ̀
- Sanwo-Olu ṣàlàyé ohun táwọn gómìnà ilẹ̀ Yorùbá ń ṣe lórí ọ̀rọ̀ Sunday Igboho
- Ó nira fún Sunday Igboho láti jẹun ní àtìmọ́lé ọlọ́pàá torí wọ́n dè é lọ́wọ́- Agbejọ́rò
- Sunday Igboho gbé DSS àti Abubakar Malami lọ sílé ẹjọ́ láti jà fún ẹ̀tọ́ rẹ̀