Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá
Èkó: Àwọn akínkánjú obìnrín tó ń wa Márúwá
Àwọn obìnrin ti wọn ń wa kẹ̀kẹ́ lẹ́sẹ̀ mẹ́ta táa mọ̀ sí kẹ̀kẹ́ Márúwá jẹun sọ pé isẹ́ náà kò dí àwọn lọ́wọ́ iṣẹ́ ilé.
Awọ́n akinkanju obinrin to n wa ọkada ni ilu Eko ní isẹ́ náà pé ju kí èèyàn máa se òwò nàbì lọ.
Ọ̀kan nínú wọn ní àwọn tó ń bá oun wa kẹ̀kẹ́ náà tẹ́lẹ̀, kìí se sọ òtítọ́ ló mú kí òun máa wa kẹ̀kẹ́ náà fúnra ara òun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- ‘Èpè ni Toyin Abraham sẹ́ fún mi nínú ìgbìyánjú mi lórí ìgbeyàwó rẹ̀ tó dàrú’
- Àwọn ọmọ Iyabọ Ojo rí Bàbá lẹ́yìn ọdún mẹ́fà
- Fídíò bí Ìwé títẹ̀ ní Sómólú l‘Eko se dára ju ti China lọ
- Atagitá Fẹ́mi Aníkúlápó-Kútì bá obìnrin lọ l‘Amẹ́rika
- Ikọ̀ ẹlẹ́sìn Hàkíkà rèé, níbití wọn ti ń pààrọ̀ ìyàwó láàrín ara wọn
- Òwò Àdìrẹ bùyààrì ní Abẹ́òkúta
- Justice Osei le dún bíi ẹranko 50
- Túnbọ̀sún Ọládàpọ̀: Òǹkọrin ni etí Ọba láti sọ òdodo