Obafemi Awolowo: Nínú ilé tí wọ́n kó ńkan ídánimọ̀ Baba Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ sí
Obafemi Awolowo: Nínú ilé tí wọ́n kó ńkan ídánimọ̀ Baba Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ sí
Àgbà ọ̀jẹ̀ olósèlú tó tún jẹ́ gbajúgbajà ọmọ Yorùbá ni Obáfẹ́mi Awólọ̀wọ́ nígbà ayé rẹ̀.
Wo awọn nkan to wa nile oloogbe agba iran Yoruba naa, Oloye Obafemi Awolowo ni ilu rẹ ni Ikenne Remo nipinle Ogun ni Iwo oorun guusu Naijiria.
Nibẹ ni a ti ri awon nkan ti ọkọ Hannah Idowu Dideolu Wolowo lo kẹyin nigba aye rẹ bii kóòmù iyarun, atike mọju, ipara, ọkọ ayokẹlẹ to fi polongo idibo ọdun 1979 ati 1983\.
Tun wo ibi ti wọn sin olori iran Yoruba naa si ni Ikenne
Iru awọn iroyin ti ẹ le nifẹ si:
- Itan Omi Erin
- Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
- Mọ̀ sí i nípa Oba Yesufu Asanike, Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- Àwọn obìnrin ológun tó kojú àwọn amunisin nílẹ̀ Áfríkà
- Ṣé agbégbé ilẹ Afirika tó ní àṣeyọrí jùlọ nì yí?
- Bí mo ṣe kó N5 mílíọ̀nù mi àkọ́kọ́ jọ nígbà tí mo pé ọdún 21- Iyalaje Oodua Toyin Kolade
- Ìtàn nípa orúkọ àdúgbò tó níí ṣe pẹ̀lú ìjà Oyo, Fulani àti Ilorin ní 1835
- Ìdí tí wọn kii fi jẹ́ kí obìnrin jẹ Ọ̀ọ̀ni ni Ile Ife
- Ọba Lamidi Adeyẹmi, òṣìṣẹ́ adójútòfò àti Abẹ̀ṣẹ́kùbíòjò kó tó jọba