Koko iroyin: Àyẹ̀wò di ọ̀ranyàn ni sọọsi, Ẹ̀mí èṣù ni okunfa ipààyàn Benue

Eyi ni awọn akojọpọ iroyin ti toni.

Ìjọ Redeem: Àyẹ̀wò ojú ara wà láti dènà ìjà nínú ìgbeyàwó

Oríṣun àwòrán, @PastorFOdesola

Àkọlé àwòrán,

Ìgbésẹ̀ náà ló wà láti dènà ọ̀pọ̀ lààsígbò ló ń mi ìgbeyàwó lògbò-lògbò

Ìjọ Ìràpadà ti ẹ̀mi, táa mọ̀ sí The Redeemed Chriatian Church of God (RCCG) ti fi àtẹ̀jáde tuntun kan síta.

Atẹjade naa wi pé, láti àkókò yìí lọ, àwọn àfẹ́sọ́nà tó bá fẹ́ se ìgbeyàwó nínú ìjọ náà, ni wọn yóó máa se àyẹ̀wò fúń ṣáájú ìgbeyàwó lórí àwọn ohun to so rọ̀ mọ́ ìbálòpọ̀ àti ìbímọ wọn.

Buhari: Ìwà èṣù pátápátá ni ìkọlù àti ìpànìyàn nípínlẹ̀ Benue

Oríṣun àwòrán, Benue state government

Àkọlé àwòrán,

Ẹni to ba n pa eeyan ti sọ alaafia rẹ nu, o si ti di ẹni itanu ati ẹni ifib

Aarẹ Muhammadu Buhari ni ẹmi esu lo n gbe inu awọn to n pa eeyan ni ipinlẹ Benue.

Igbakeji aarẹ, Ọjọgbọn Yẹmi Oṣinbajo, lo ṣoju fun aarẹ Muhammadu Buhari nibi eto isinku naa.E ka ekunrere re ni bii

Awọn nkan miran ti ẹ ni lati mọ loni

Gbọ iroyin iṣẹju kan BBC

Fidio wa fun toni

Ìtakurọ̀sọ máa ń jẹ́ kí ìsọ̀ ìwé ìròyìn dùn

Àkọlé fídíò,

Ìsọ̀ oníwe ìròyìn àtàwọn tó ń kà a lọ́fẹ̀ẹ́