Akeeb Kareem: Iléesẹ́ tó gbé àwo orin Ámẹ̀bọ jáde yàn mi jẹ
Akeeb Kareem: Iléesẹ́ tó gbé àwo orin Ámẹ̀bọ jáde yàn mi jẹ
Láàrin àkókò ọ̀dún 60s sí 80s ni àwọn àwo orin Akeeb Kareem, tí ó tún ńjẹ́ Blackman gbilẹ̀ kan ní Nàìjíríà. Akeeb Kareem ti gbé iṣẹ́ orin kíkọ tayọ agbègbè orílẹ̀èdè Nàìjíríà nìkan.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Akeeb ni ibasepọ oun ati awọn ileesẹ ilẹ okeere to n gbe awo orin jade ko lọwọ magomago ninu rara.
Amọ o ni, igba ti oun gbiyanju lati se awo orin ni Naijiria, ni wọn ko fun oun ni ẹtọ toun lori awo orin ti oun gbe jade, tii se Amẹbọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Obìnrin tí kò bá rẹwà ló ń ṣí ara sílẹ̀ - Ṣọla Allyson
- ‘Ọ̀rẹ́ mi ní kí n fi ‘acid’ sí oúnjẹ ọmọ mi’
- Akẹ́kọ̀ọ́gboyè ní mí ṣùgbọ́n aṣọ òké ló ń pawó wọlé'
- Ǹjẹ́ o mọ̀ pé Baba Sala ló kọ́ Sunny Ade nísẹ́?
- ‘Alẹ́ làwọn ọkùnrin fẹ́ bá mi jáde, torí mo kọ ilà’
- ‘Ó sojú wa nígbàtí ọkọ̀ agbépo pa ènìyàn mẹ́rin n‘Ibadan’