Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa
Violence against Women: Àlùfáà Joel Olugbenga: Bíbélì kò ní kéèyàn dúró títí ọkọ rẹ̀ yóò fi lù ú pa
Ìwà ipá nínú ilé ti rìn jìnà gẹ́gẹ́ bíi kòkòrò ajẹnirun tó ti ń tú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdílé ká. Ṣùgbọ́n àwọn onímọ̀ ẹ̀sìn sọ pé ohun àá ṣeé ṣì kù.
Oriṣiriṣi nnkan lo n ṣẹlẹ lasiko yii, ni eyi to ti n mu ki a nlu ara ẹni n waye ninu idile.
Ni igba miiran, awọn iṣẹlẹ yii maa n ṣokunfa iku ọkọ tabi aya ni asiko yii.
BBC Yoruba gbalejo Alagba Joel Olugbenga lati ile ijọsin Redeemed Christian Church of God lati sọrọ lori ohun ti Bibeli sọ lori kikọ ara ẹni silẹ ninu idile.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ sí:
Oluṣọagutan Joel Olugbenga, to jẹ APICP FCT 6 nilu Abuja gba awọn kristiẹni nimọran lori ọrọ ipa ninu idile.
O sọju abẹ niko pe igbeyawo ko gbọdọ la ẹmi lọ mọ, ẹ le yẹra funra yin ki alaafia fi jọba.
- Àwọn ọlọ́pàá ti fi páńpẹ́ òfin gbé ọkọ olórin ẹ̀mí “Ekwueme” fẹ́sùn lílu ìyàwó rẹ̀ dójú ikú
- Oko kìí jẹ́ ti baba tọmọ kó mà ní ààlà; Mi ò ní ọmọ tó dàgbà tó le jáde láti dupò Ààrẹ- Tinubu
- Àwọn agbébọn ṣekúpa alága APC ní ìpínlẹ̀ Osun, ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
- Èèmọ̀ wọ̀lú! Àwọn agbébọn pa ènìyàn 135 lọ́jọ́ kan ṣoṣo
- Mo fi Ọlọ́run bẹ̀ yín, ẹ má bú ọkọ mi mọ́ torí ìgbéyàwó wa tó túká - Yewande Adekoya
- Ṣé o mọ ìgbésẹ̀ ìkọ̀sílẹ̀ lábẹ́ òfin Naijiria?
- Wo dókítà ọmọ Nàìjíríà tí àgbáyé ń wárí fún nítorí abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19
- Àyè wá dà, èmi ti ní ọ̀rẹ́kùnrin míràn nítèmi o - Nkechi Blessing
- Mò ń bọ̀ nílé láìpẹ́, ìjọba yóò sanwó tó jẹ mí - Sunday Igboho