Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Mọrèmi: Ọọ̀ni ní láìsi Mọrèmi, kò leè sí ilẹ̀ Yorùbá
Awọn eekan ilu lọ̀kunrin ati lobinrin lo peju si ibi ayẹyẹ ifilọlẹ ere ati orin itan igbe aye akọni obinrin ilẹ Yoruba nni, Mọremi Ajansoro.
Ọọni Ile ifẹ́, Ọba Adeyẹye Ẹnitan Ogunwusi, Ọjaja keji ni, ko yẹ ka maa foju tẹ́mbẹ́lu awọn obinrin lawujọ̀, toripe wọ̀n n se bẹbẹ lati to ẹbi ati ilu wa.
Lai Muhammed, ninu ọrọ rẹ ni, kan saara si aya gomina ipinlẹ Ogun, Olufunsọ Amosun, to gbe owo kalẹ lati se onigbọwọ ere ati orin itan igbe aye Mọremi Ajansoro.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú
- Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
- Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
- Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
- Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
- Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde
- 'Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ'
- Ṣẹ gbọ́ nípa Alájọ Ṣómólú, tó ta mọ́tò ra kẹ̀kẹ́?
- Yorùbá dùn lédè, ẹ máa sọọ́
- 'Mo máa ń parọ́ díẹ̀díẹ̀ ṣùgbọ́n kò pọ̀'
- Irú ẹ̀dá wo ni olówó yalumọ àkọ́kọ́ nílẹ̀ Yorùbá, Candido Da Rocha?
- Níbo làwọn òṣèré apanilẹ́rìn ín wọ̀nyí tó pilẹ̀ sínima àgbéléwò Yorùbá wà?
- International Women's Day: Kí ni pàtàkì àyájọ́ àwọn obìnrin lágbáyé fún Áfíríkà?
O wa rọ awọn ọmọ ilẹ yii lati maa gbe aṣa ilẹ wa larugẹ, nitori ọpọ ohun alumọni wa lo ti sọnu laisi ẹni ti yoo wa.
Lero ti Bọlanle Austen-Peters, to se Mọremi ninu ere naa, o gba pe itan Yoruba dun, ohun si lawọn eeyan nile ati loke okun fẹ gbọ, eyi ti yoo se afihan idamọ wa si iran miran.