Ìgunnukó: Àwọn Tápà gbà pé ẹni tó bá ń sin Ìgunnukó kò ní ráùn ohun rere
Ninu irinajo ikọ BBC Yoruba si ilu Porto Novo, lọdọ ẹya Tapa, a foju se mẹrin bi wọn se n bọ orisa Igunnuko nibẹ.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, Ọba Tapa ni ilu naa salaye pe, orisa yii lo jẹ ti ẹya Tapa, to gbera lati Porto Novo lọ tẹdo si ilu Abẹokuta, lọ de agbegbe Dahomey.
- Coronavirus: Gómìnà Wike ìpínlẹ̀ Rivers wó ilé ìtura méjì lulẹ̀ torí wọ́n tàpá s'ófin kóńlé-ó-gbélé
- Àwọn nǹkan tí obìnrin lè ṣe pẹ̀lú olólùfẹ́ oníwà ipá lásìkò ìgbélé Coronavirus yìí
- Coronavirus: Ǹjẹ́ àwọn dókítà tó ń tọ́jú eyín ń ṣisẹ́ lásìkò pàjáwìrì? Àti àwọn ìbéèrè míràn
- Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá
O fidi rẹ mulẹ pe, orisa ọlọmọ ati olowo ni Iguunuko, orisa to n se ohun rere fun ilu ni.
Bi ilu ba si daru, bi ile kan ba gbona, ti wọn ba pe orisa igunnuko, ayọ yoo pada wọ inu ile naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Kíni ìwọ mọ̀ nípa Funmilayọ Ransome-Kuti?
- Ẹfunsetan Aniwura, obìnrin tó ju ọkùnrin lọ
- Hubert Ogunde rèé, baba àwọn òsèré tíátà
- Kí lo fẹ́ mọ̀ nípa ‘Ajala Travels’?
- Wòlíì Kasali ní Dolapo Awosika kò lé ìyàwó òun jáde
- Àwọn àṣà àti ìse tó yọ obìnrin sílẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá
- Eré Mọrèmi rèé, obìnrin tó gba Ilé-Ifẹ̀ là lọ́wọ́ ìparun
Fatimoh Gomez, Hakeem Malọmọ atawọn abọrisa igunnuko yoku gba pe, obinrin lo bi orisa igunnuko, lawọn obinrin se maa n ki i.
Wọn ni ire to wa ninu bibọ orisa Igunnuko ko nipẹkun, asa ajogunba wa ni, ko si yẹ ka gbagbe rẹ.
Wọn wa rọ gbogbo ẹya Tapa, to jẹ ẹya Yoruba lapapọ, lati maa sin orisa Igunnuko bo se yẹ.