Yoruba Culture: Ọjọ́ méje ni wọ́n fí n rẹ ẹ̀kú Danafojura kó tó jáde
Ojúbọ Ogun àti Eṣu ṣe pataki si eegun Danafojura - Danafojura
Aṣa ati iṣe Yoruba ṣe pataki si BBC Yoruba ki a to ṣẹṣẹ wa sọ ti iṣẹṣe ati igbagbọ awọn Baba nla wa.
Oriṣiriṣi eegun lo wa nilẹ Yoruba ṣugbọn ọtọ ni ti eegun Danafojura to n jade ni ilu Ogbomọsọ ni ipinlẹ Oyo ni guusu Naijiria.
- Ìrìnàjò Toyin Abraham, láti orí gbèsè jíjẹ, ó di onílé, onimọto àti aya lọ́dọ̀ ọkọ
- Ẹni ọdún mẹ́rin ni mo bẹ̀rẹ̀ Kéwú, 1967 ni mo ṣe wòlímọ̀, mo lè kéwú láti ìbẹ̀rẹ̀ dópin- Tunde Bakare
- Mo ti kìlọ̀ fún Sunday Igboho tẹ́lẹ̀ pé wọ́n má a gbé é nítorí pé ọ̀dàlẹ̀ ní Yorùbá- ESABOD
- Olórí ọ̀dọ́ ẹgbẹ́ PDP sọ àbùkù ọ̀rọ̀ sí Ààrẹ Buhari àti SGF, ẹ̀wọ̀n jàntò ló rí he!
- Ogun àgbáyé ni COVID-19, ìgbọ́nran sáwọn ìjọba lẹ́nu ṣe pàtàkì-Ọọ̀ni Ilé- Ifẹ̀
Oloye Sunday Babatunde Olalere to n gbe eegun Danafojura lọwọ ṣalaye lẹkunrẹrẹ ohun to sọ akọwe ijọ di eegun l'Ogbomọṣọ.
- 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!"
- Kayeefi: Deji pa èèyàn mẹ́sàn án nítorí ìfẹ́
- Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
- Òfin lè má mọ ògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi - Baba Favour
- N30,000 ni mo gbà fún orí, ọwọ́ àti ẹran ara wòlíì Bosede - Kayeefi
Oyinlọla Olalere, iya Danafojura sọrọ lori itan eegun naa ati igbagbọ awọn eniyan nipa eegun naa pe o n gbọ adura awọn eniyan.
- Kìí ṣe gbogbo ohun tí dókìtà ni kí n má jẹ torí àìsàn jẹjẹrẹ ni mo tẹ̀lé- Soyinka
- Itan omi gbigbona ati tutu ni Ikọgosi Ekiti
- Ìyálé àti ìyàwó bínú di omi gbígbóná àti tútù
- O ṣójú mí kóró bí wọ́n ṣé fí àdó olóró pa Dele Giwa lọdún 1986- Soyinka
- Seun Egbegbe lo ọdún méjì àti oṣù méje lẹ́wọ̀n láì tìí san béèlì rẹ̀
Ọpọlọpọ eewọ ati iṣẹse lo rọ mọ gbigbe eegun naa jade ni Ogbomọṣọ.
Yoruba ni ooṣa ti a ko ba fidi ẹ han ọmọde kii pẹ parun ni BBC ṣe lọ ṣe iwadii nipa eegun yii, kawọn ọdọ Yoruba le mọ pe agbara ṣi wa lọwọ awọn agba Oodua.
Epo pupa ati iyọ ṣe pataki lojubọ ki danafojura to jade.
- Mo sá kúrò nílé tí mo yá mílíọ̀nù 17 kọ́ ní Àkútè- Bayo Okeowo
- Wo ibi tí '1st Plane Crash' ní Afrika ti ṣẹlẹ̀ ní Ikogosi Ekiti ní Nàìjíríà
- Kí ló mú kí géńdé múra bí obìnrin láti bá ọ̀rẹ́bìrin rẹ̀ kọ ìdánwò?
- Wo àgbáríjọpọ̀ àwọn Arugbá Ọ̀ṣun Òṣogbo látìgbà tó ti bẹ̀rẹ̀
- Ṣàǹgbá fọ́! Ìrètí Nàìjíríà fún góòlú, Adekuroye pòfo nínú ìjànkadì ní Tokyo 2020