Yatọ si ọrọ tawọn ọmọ Naijiria n sọ loju opo Twitter awọn agbẹjọro fawọn oludije mejeeji ti ọrọ igbẹjọ idibo Gomina ipinlẹ Oyo kan naa sọ ti wọn.
Kete ti wọn jade lati inu ile ẹjọ ni wọn ṣalaye fawọn oniroyin oun to kan lẹyin tawọn adajọ sọ ti wọn.
Ẹkunrẹrẹ fidio naa la fi soke yi ki ẹ ba le mọ bi ọrọ naa ti ṣe n lọ.
- Makinde vs Adelabu: Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ ní Nàìjíríà ní yóò yanjú ọ́rọ́ ìdìbò Gómìnà Oyo
- Àwọn alága ìbílẹ̀ tún wọ́ Seyi Makinde relé ẹjọ́
- Emir Bornu lé àwọn aṣẹ́wó léré, ó ní kò sáyè fúnwọn nípìnlẹ̀ òun
- Wo bí wọ́n ṣe ṣe ọjọ́ ìbí Anọbi ní Abuja ati ní Ghana
Ọpọ awọn eniyan lo ti n sọrọ lori ayelujara pe idajọ naa ri ba kan ba kan.
Koko kan ṣoṣo to daju ni pe ipade awọn mejeeji di ile ẹjọ giga julọ.
- Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?
- Burna Boy fẹ́ yọ̀ǹda owó tó bá pá lóde àríyá f'áwọn tó farakásá ìṣẹ̀lẹ̀ Xenophobia
- Òjò ló lè mú kí ìtànkálẹ̀ àrun ìgbẹ́ ọ̀rìn má tètè dópin ni Eko- Iléeṣẹ́ ìlera
- Emir Bornu lé àwọn aṣẹ́wó léré, ó ní kò sáyè fúnwọn nípìnlẹ̀ òun
- Aàrẹ, igbákejì aàrẹ àti aàrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kọ̀wé fipò sílẹ̀ lọ́jọ́ kan náà
- Ẹ wo àwọn ààrẹ tí ikọ̀ ọmọ ogun ti gba ìjọba lọ̀wọ̀ wọn