Ẹsẹ ko gba ero nile ijọba to wa nilu Ibadan loni nigba ti ọpọ ero wa se abẹwo awa lẹyin rẹ si gomina Seyi Makinde lati safihan ifẹ ti wọn ni si.
Nigba to n gbalejo awọn ọgọọrọ eeyan naa, Gomina Seyi Makinde ni se ni ẹgbẹ oselu APC dabi afomọ ti ko ni gbongbo, to si n wa gbongbo ti yoo dirọ mọ pẹlu asẹ ile ẹjọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Iléeṣẹ́ ológun, ẹ kú àpọ́nlé mi, èmi náà yóò máa ṣúgbàá yin - Seyi Makinde
- Òfin ọ̀dájú ni àṣọ́bodè ṣe pé epo kò gbọdọ̀ dé ẹnu bodè Nàíjíríà - Ilé aṣojú-ṣòfin
- Àwọn èèyàn fi ìtara ba ilé ìjọsìn jẹ́ nígbà tí ọmọ olùjọ́sìn kan di àwátì
- Ẹ gbà wá o! Ìbọn àti afẹ́fẹ́ aláta ní DSS fi tú wa ká lásìkò ìwọ́de fún ìdásílẹ̀ Sowore
- Ká máa sọ òyìnbó nínú eré Yorùbá ń ba àṣà wa jẹ́ - Damola Olatunji
O fikun pe ohun to n waye ni ipinlẹ Ọyọ ko lee dabi awọn isẹlẹ to ti waye sẹyin nipinlẹ Ọsun ati Ekiti nibi ti idajọ ile ẹjọ ti le ijọba to wa lori aleefa kuro.
- Ìjọba Ọyọ yàtọ̀ sí ti Ọṣun àbí Ekiti tí APC leè fi àṣẹ iléẹjọ́ lé dànù - Seyi Makinde
- Jálà epo bẹntiróò di N600 nítorí ibodè títìpa
- Orílẹ́èdè Nàìjíríà ni ìtànkálẹ̀ òtútù ìgbá àyà tí pọ̀ jù lọ lágbàáyé
- Olùdásílẹ̀ Twitter bá wọn jó 'Soapy' ní Nàìjíríà , ó fi òǹtẹ̀ jan Tacha
- Ta ni Ken Saro-Wiwa tí ìjọba ológun sekúpa?