Ọwọ́ palaba kánsẹ́lọ̀ tẹlé rí olórí adigunjalè tó n jí ọkọ̀ ní Kwara segi

Kansẹlọ tẹlẹri kan ni ijọba ibilẹ Ekiti ni ipinlẹ Kwara ti ko si panpẹ ajọ to n gbogun ti iwa jẹgudujẹra ni Naijiria, ìyẹn EFCC.
Ẹsun ti wọn fi kan an ni pe o jẹ olori awọn adigunjale to n fi ọna ẹburu ji ọkọ ayọkẹlẹ.
Loju opo ajọ naa ni wọn fi ikede yi si pẹlu alaye pe ọgbẹni Samuel Opeyemi Adeojo ni o jẹ agbatẹru awọn adigunjale kan ti wọn maa n fi ọna ẹburu ji ọkọ awọn onisowo ọkọ.
- Ewé súnko! Ọ̀wọ́ EFCC tẹ ayédèrú Babaláwo pẹ̀lú òògùn abẹnugọ̀ǹgọ̀
- Iṣọla Oyenusi rèé, ẹnití ìfẹ́ obìnrin ṣun dé ìwà ìdigunjalè
- Ọ̀nà tó fi le è mọ gbájúẹ̀ babaláwo - Ẹlẹ́buìbọn
- Ọwọ́ tẹ babaláwo àti adigunjalè márùń ni Imo - Olọpàá
Gẹgẹ bi ohun ti ajọ naa sọ, wọn ni o to ọjọ mẹta ti awọn ti n wa Adeojo ki o to wa di pe ọwọ tẹ ẹ.
O kere tan wọn ti fi idi ẹjọ mẹta mulẹ lori ẹsun ti wọn fi kan ikọ adigunjale yii ti wọn si ti gba ninu awọn ọkọ ti wọn ji gbe lọwọ wọn.
Awọn ọkọ naa wa ni ileeṣẹ ajọ EFCC to wa ni ilu Ibadan.
- EFCC fẹ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilé tí mo fi owó ìfẹ̀yìntì kọ́ nílùú Ilorin- Saraki
- Buhari já ọ̀ra lára ọkọ̀ ìjagun ológun tiwantiwa ní Kaduna
- 'A kò ní w'ojú olóṣèlú kankan lóríi ìwádìí àpapín owó N5bn ní Kwara'
- Ilé ẹjọ́ Eko pàṣẹ, EFCC mú u ṣẹ, Ìjọba gbẹ̀sẹ̀ lé ilé Saraki ní Ilorin
Iwadii EFCC gẹgẹ bi alaye wọn ṣe, ni o jẹ ki wọn mọ ọgbọn tawọn ole naa n lo lati fi ji ọkọ awọn eeyan.
- Messi ló gb'àmì ẹ̀yẹ Ballon D'or lóòtọ́ọ́, àmọ́ Ronaldo ló dára jùlọ (GOAT)- Mendes
- Mọ̀ síi nípa Oyedele Adedokun tó ya àwòràn Donald Trump tó lu ayélujára pa
- Wo bí àwọn àkàndà ẹdá ní Akurẹ ṣe sàmì àyájọ́ ọjọ́ wọn
- LASTMET kọ́ ló kó Opay nílẹ̀ ṣùgbọ́n ọlọ́kadà kò láṣẹ látigba ọ̀nà mọ́rosẹ̀ l'Eko- Opeifa
