BIAFRA War armed forces remembrance: Ìhàlẹ̀ ológun ni Gowon ni ká kọ́kọ́ fi bẹ̀rẹ̀, ẹsẹ̀ akẹ́gbẹ́ mi méjèjì ló gé - Aladejebi
Awolowo lo jawe olubori ninu idibo ọdun 1966 - Aladejẹbi.
Ogun Biafra jẹ ogun abẹle ti Naijiria ja pẹlu awọn iran Igbo lọdun 1967 si ọdun 1970.
Ogun yii sọ ọpọ ẹmi ati dukia nu ni eyi ti Naijiria n ṣe iranti aadọta ọdun to waye.
Ọkan lara ọmọ ogun ilẹ to kopa ninu ogun nigba naa, Baba Gabriel Aladejẹbi ba BBC rin irinajo ohun ti oju rẹ ri lasiko ogun Biafra.
- Ìdìbò 2023: Àwọn ìpèníjà tí Bola Tinubu yóò kojú nínú ìrìnàjò rẹ̀ nìyí
- 1967 sí 1970, gbọ́ ẹ̀dà ìtàn míì nípa ogun Biafra látẹ́nu "Ìyá àgbà"
- Ǹjẹ́ o mọ ipa tí ẹja Panla kó lásìkò ogun abẹ́lé Biafra?
- Ọ̀rúnmìlà ni ó kọ́kọ́ lo 'Google' láàgbáyé-Ọ̀ọ̀ni Ìlẹ̀ ifẹ̀
- 'Ẹ má gbọ́kàn lé ewé o, ẹ má gbọ́kàn lé oṣo tàbí àjẹ, Ọlọrun nìkan ni “Oniduro wa!'
- Ọmọ ọdún mẹ́jọ ni mo ti ń bá Adẹ́rùpọkọ̀ ṣe eré tíátà - Tope Alabi
- Wo nkan tó yẹ́ kí o mọ̀ nípa gbajúmọ̀ oníwàásù 'Lórí irọ́'
- Adeboye, Ayodele, Enenche sọ àṣọtẹ́lẹ̀ fún 2023
- Èmi ni mo yọ "wipes" fi nu omi ẹkún to ti gbẹ́ àti ikun ní'mú òkú ọmọ tí wọ́n gbé lé mi lọ́wọ́ - Ìyá Ojo Emmanuel
Gabriel sọ nipa awọn igbesẹ ati aṣẹ ti Ọgagun Yakubu Gowon pa lasiko ogun yii titi di ọjọ ti Phillip fi kede pe iran Igbo ko ja ogun Biafra mọ lọdun 1970
Baba Aladejẹbi sọ nipa awọn ẹmi, dukia ati ohun ti o ba ogun Biafra rin nigba naa ati ero awọn eniyan to kopa ninu ogun ọhun
Aladejẹbi sọ nipa iya ati ipenija ti awọn ọmọ ogun fẹyinti n koju ni isinyi ni eyi ti ijọba ko pese iranlọwọ bi o ti yẹ.