Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjèèjì ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
Oman Returnees: Ọ̀kan lára àwọn obìnrin méjèèjì ní òun ṣiṣẹ́ ọdún kan láì mú ₦5 padà wálé
Awọn obinrin meji ree ti wọn lọ fi wọn sọfa ni orilẹede Oman, nibi ti oju wọn ti ri mabo.
Damilola Falodun ati Oyinlola Solanke ni ko rọrun lati ni ominira ni Oman lai jẹ pe obinrin ba ọga rẹ sun, ti awọn mejeeji si salaye itu ti awọn ọga wọn fi wọn pa lọhun.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n
- Pa Kasumu,gbajúgbajà òṣèré tíátà Yorùbá jáde láyé
- Ó dá mi lójú pé ọmọ ìjọ mi kò lé è kó àrùn Coronavirus - Adeboye
- Èdè àìyedè bẹ̀rẹ̀ lórí bí àgbélẹ̀rọ òyìnbó Nàíjíríà ṣe wọ ìwé atúmọ̀ èdè Gẹ̀ẹ́sì Oxford
- Ògbólógbòó ìjàpá rèé, tó bí ọmọ 800 kí ìran rẹ̀ má ba à parun
Bakan naa ni wọn fẹsun kan ọpọ awọn osisẹ asọbode to wa ni papakọ ofurufu Naijiria pe, wọn n lẹdi apo pọ mọ awọn to n ko awọn obinrin lọ sowo ẹrun lawọn orilẹede Larubawa.
Ẹkunrẹrẹ ohun ti oju awọn obinrin mejeeji naa ri ni orilẹede Oman ree.
Producer Yemisi Oyedepo àti Bayo Odukoya