Pa Kasumu: Lere Paimo ní àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun
Pa Kasumu: Lere Paimo ní àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun
Ilumọọka agba ọjẹ nidi isẹ tiata, Lere Paimọ ti salaye pe lọ́pọ̀ ìgbà, àìrìríjẹ́, àìrímú tàbí ìrònú má a ń jẹ́ kí ọjọ́ ogbó dagun.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iku to pa agba ọjẹ ninu tiata miran, Pa Kasumu, Paimọ ni ó yẹ kí àgbàlagbà máa rí àánú gbà, lati ọdọ awọn eeyan awujọ, kìí ṣepé èèyàn ń tọrọ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Agba ọjẹ ninu isẹ tiata naa ni omijé bọ́ lójú òun nígbà tóun rí olóògbé náà gbẹ̀yìn, nitori ipo to wa.
- Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní Oman tó bá fẹ́ òmìnira, yóò bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - obìnrin méjì tó ti oko ẹrú dé
- Ọ́lọ́pàá bá aṣọ, bàtà àti fóónù ọkùnrin tó dàwátì nílé Pásítọ̀ etí òkun l‘Eko
- Ẹ fi ọkàn balẹ̀ lórí àrùn Coronavirus, à ń ṣa ìpa wa láti dènà ìtànkálẹ̀ rẹ̀ - Buhari
- Ẹ́ fún ọmọ Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́ tó yè kooro dípò kẹ rán Boko Haram tó ronúpìwàdà lọ kàwé lókè òkun - Serap