Coronavirus: Ètò Làá hàn mí yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì, ká le è dènà Coronavirus
Coronavirus: Ètò Làá hàn mí yìí ló ń kìlọ̀ fún wa láti mú ìmọ́tótó ní pàtàkì, ká le è dènà Coronavirus
Yoruba ni igi gogoro ma gun mi loju, ati okeere laa ti lọ̀, bẹ́ẹ́ si ni ati okeere ni oloju jinjin ti n mu ẹ́kun sun.
Idi ree ti BBC Yoruba, lori eto Laa han mi se n la wa lọyẹ lori awọn ohun to yẹ́ ka se lati dena itankalẹ arun Coronavirus.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Omijé bọ́ lójú mi nígbà tí mo rí olóògbé Pa Kasumu gbẹ̀yìn - Lere Paimo
- A dúpẹ́ o! Lẹ́yìn àyẹ̀wò, kò sí alárùn Coronavirus ní Nàíjíríà, sáká lara wa dá - Mínísítà
- "Àbámọ̀ ló gbẹ̀yìn bí mo ṣe yípadà láti obìnrin sí ọkùnrin, ń kò bá tí ṣe bẹ́ẹ̀"
- Kaduna tún gbàlejò ìkọlù àwọn agbébọn, àádọ́ta èèyàn míì rọ̀run ọ̀sán gangan
Eto naa gba wa nimọran lati yẹra fun ọpọ ero, ka mu imọtoto ni pataki, ka maa se ounjẹ wa jinna daadaa, ka si joko sile, ti ara wa ko ba da.
- Àrùn Coronavirus ti tàn dé orílẹ̀-èdè míràn nílẹ̀ Afrika
- Gómìnà Oyetọla tí yi ìlànà ètò ẹ̀kọ Rauf Aregbesola pada
- Obìnrin tó ń ṣiṣẹ́ ẹrú ní Oman tó bá fẹ́ òmìnira, yóò bá ọ̀gá rẹ̀ ṣùn - obìnrin méjì tó ti oko ẹrú dé
- Ọ́lọ́pàá bá aṣọ, bàtà àti fóónù ọkùnrin tó dàwátì nílé Pásítọ̀ etí òkun l‘Eko
- Ẹ fi ọkàn balẹ̀ lórí àrùn Coronavirus, à ń ṣa ìpa wa láti dènà ìtànkálẹ̀ rẹ̀ - Buhari
- Ẹ́ fún ọmọ Nàíjíríà ní ẹ̀kọ́ tó yè kooro dípò kẹ rán Boko Haram tó ronúpìwàdà lọ kàwé lókè òkun - Serap
Ẹ wo fidio yii lati mọ si nipa arun asekupani Coronavirus ati ba se lee bọ lọwọ rẹ.