Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ to yẹ ló ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́
Peter Fatomilola ní àìsí ẹ̀kọ́ to yẹ ló ń mú káwọn òṣèré tíátà ó máá ṣe oun tí kò tọ́
Laye ọjọsi, ere itage jẹ gbajugbaja lawujọ awọn onitiata lorilẹede Naijiria.
Ọpọlọpọ awọn ọjọgbọn lere tiata lo si ti n pariwo pe eku ko ke bi eku mọ lori ipa ti tiata n ko lori idagbasoke awujọ.
- Bí Fayemi bá tasẹ̀ àgẹ̀rẹ̀, àwọn oníbáwí rẹ̀ wà l'Ekiti-Peter Fatomilọla
- Nílé ijó Fẹla Anikulapo, àrùn Coronavirus dá fàájì dúró
- Àwọn ọba Yorùbá kan rèé tí wọ́n rọ̀ lóyè, tí ọba míràn jẹ lójú ayé wọn
- E yé ṣíra yín s'íhòhò nínú fíìmù, àṣà burúkú ni- Efusetan kìlọ̀ fáwọn òṣèré
- Lóòótọ́ lòògùn owo wà ṣùgbọ́n ayédèrú aláwo ló ń lo ẹ̀yà ara -Ẹlẹ́búìbọn
- Ìyàwó Aṣọbodè, Sọ́jà àti Ọlọ́pàá náà ń kó ẹrù wọlé sí Nàìjíríà lọ́nà àìtọ́- Senatọ Fadahunsi
Alagba Peter Fatomilsla, ọkan lara awọn odu elere tiata lorilẹede Naijiria, toun pẹlu kopa lasiko ere itage ṣalaye ohun to ṣẹlẹ ati ibi ti ọrọ ti wọ wa.