Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Yorùbá
Nollywood stars: Àwọn èèkàn òṣèré sinimá ní Nàìjíríà jẹ́wọ́ ara wọn lórí fífi àmì ohùn sí ọ̀rọ̀ Yorùbá
Wọn ni oogun ti a ko ba fi han ọmọ ẹni kii pẹ parun.
Ọpọ lo n kọminu lori ede Yoruba ati bi ti yoo de duro nigba ti a o ba fi ri asiko diẹ si.
Eyi lo mu ki ikọ BBC News Yoruba tọ diẹ lara awọn amuludun ti wọn n fojojumọ gbe sinima Yoruba jade pe, bawo ni lori fifi ami ohun si ọrọ Yoruba. Abọ wa niyi, Ẹ gbe e yẹwo.
- Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin
- Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo
- Mo fẹ̀ lọ gba owó oúnjẹ lọ́wọ́ bàbá mí ni mo bá wọn tí wọ́n ti pokùnso- Ọmọ Oloogbe
- Eyín ọ̀ọ́kán mi ni Barakat tí wọ́n pa lẹ́yìn tí wọ́n fipá bá a lòpọ̀- Ìyá Barakat
- IGP ti jọ̀wọ́ Hamisu Wadume fún aádájọ́ àgbà Nàìjíríà
- Èmi ni Ààrẹ tó ṣe rere fún ilẹ̀ adúláwọ̀ jù - Donald Trump
- Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN
- Kí ni ìdí tí ilé ẹjọ́ tún ti sún ìgbẹ́jọ́ Alfa Babatunde Sotitobire síwájú
- Ohun mẹ́fà tí àgbáyé kò mọ̀ nípa Majek Fashek tó d'olóògbé nìyí
- Ọwọ́ ọlọpàá tí tẹ ọ̀kan nínú àwọn ọ̀daràn tó ṣekú pa Uwaila