Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa
Azeezat Shomuyiwa : Oyún oṣù méje ló wà nínú Azeezat, kí wọ́n tó f'òkúta fọ́ ọ lórí pa
Lẹyin igbeyawo nilana Musulumi ti wọn n pe ni Nikkah, ireti Alfa Ridwan ati Iyawo rẹ Azeezat ni pe lẹyin oṣu mẹsan ki wọn wa ba wọn ṣe isọmọlorukọ, iyẹn 'suna'.
Asiko imuṣẹ ala rere yii n sun mọ dẹdẹ ni Alfa Ridwan ba ni ki iyawo rẹ o maa bọ nile wa bimọ sọdọ awọn obi oun lo ba di wi pe iroyin iku aya rẹ ni wọn fi ranṣẹ sii pada ni ilu Kano.
Hmmm...Eduwa ko ni jẹ ka kagbako o, ẹkunrẹrẹ itan awodamiloju yii la mu wa fun yin loni, ẹ wo fidio rẹ loke yii.
- Ìfipábánilòpọ̀ kìí ṣe ìwà ọmọlúwàbí, àwọn òṣèré tíátà pariwo síta
- Iyabo Ojo, Toyin Abraham, Mercy Aigbe, ta làwọn òṣèrébìnrin yìí gbè lẹ́yìn lórí ọ̀rọ̀ ìfipábánilòpọ̀?
- Ṣé lóòtọ́ ni òjòjò dá Abiola Ajimobi wólẹ̀?
- Ọjà Ọba ní Akure ni ọwọ́ ọloọ́pàá ti tẹ aláàrùn Covid-19 tó sá kúrò ní ilé àyẹ̀wò – Akeredolu
- #JusticeforTina: Àwọn obi Tina Ezekwe ń bèrè fún ìdájọ́ òdodo pẹ̀lú omijé lójú
- ₦35,000 ni mò ń gbà bíi Adelé ọba, kò sí ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́ - Adelé Olúbọ̀rọ̀pa
- Kàyééfì BBC News Yorùbá gbé òtítọ́ òògun owó yẹ̀wò
- Ọmọdé yóò máa sọnù ládùúgbò, arúgbó leè kú láì tọ́jọ́, tí wọn bá jókòó sílé lásìkò ìjọsìn - CAN
- Ìdájọ́ ikú ni a fẹ́ fún àwọn afipábánilòpọ̀ - Ẹgbẹ́ ajàfẹ́tọmọnìyàn
- Yorùbá kìí ṣe egúngún oníhòhò, ìwà wèrè ni sinimá oníhòhò táwọn òṣèré kan ń ṣe- Lere Paimo
- Ẹ̀wọ̀n gbére ni fún ẹnikẹ́ni tó bá fipá bánilòpọ̀ ní ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun
- A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí kíkún nípa àwọn tó lọ́wọ́ nínú ikú Barakat Bello - Iléeṣẹ́ ọlapàá
- Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀