Nigeria prison experience: Abass Owonikoko dèrò ẹ̀wọ̀n fún ọdún 27 torí ìwà ìpáǹle, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Nigeria prison experience: Abass Owonikoko dèrò ẹ̀wọ̀n fún ọdún 27 torí ìwà ìpáǹle, kó tó gba kéú lọ́gbà ẹ̀wọ̀n
Yoruba ni fi ọrẹ rẹ han mi, ki n sọ iru eeyan to jẹ nitori aguntan to ba n ba aja rin yoo jẹ igbẹ.
Bẹẹ ni ọrọ ri pẹlu ọkunrin kan, Abass Abiodun Owonikoko, tii se onisowo ounjẹ lọja Bodija nilu Ibadan.
Awọn isẹlẹ Kayeefi miran ti ẹ le nifẹ si:
- Kayeefi: Deji pa èèyàn mẹ́sàn án nítorí ìfẹ́
- Àwọn èèrò ìwòran ní kóótù gbalé ẹjọ́ dọ́gbà ẹ̀wọ́n l'Ọṣun
- Òfin lè má mọ oògùn ṣùgbọ́n èmí gbàgbọ́ pé ǹkan wà nídìí bí wọ́n ṣe pa ọmọ mi- Baba Favour
- Dánáfojúrà nìyí, abàmì eégún tí ń gbé inú iná ṣọlá
- Kàyééfì BBC News Yorùbá gbé òtítọ́ òògun owó yẹ̀wò
- Kí ló le è mú kí ìlú kan ó já ọmọge mẹ́rin sí ìhòhò?
- Wòólì Ajayi kú ní ìlú Àgelú, òkú rẹ pòórá, ìjọ sin pósí lásán!
Ija ni Owonikoko atawọn ọrẹ rẹ mẹrin miran lọ ja lẹyin eegun lọdun 1993, ti wọn si pa eeyan meji.
Eyi lo ba de ọgba ẹwọn, ti wọn fi dajọ iku fun, sugbọn ti gomina Ibikunle Amosun ba yi pada , to si gba idande lẹyin ọdun mẹtadinlọgbọn.
Inu ọgba yii lo wa to fi di imaamu, o keu, to si gba alukurani.
Àwọn ìtàn Mánigbàgbé tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìtàn ayé Henry Fajemirokun, olówó tó fi owó mọ Olúwa àti ènìyàn
- Ìtàn ayé Taiwo Oredein rèé, àgbà òṣèlú tó parí ayé rẹ̀ sọ́gbà ẹ̀wọ̀n
- Ìtàn ìgbé ayé Bode Thomas rèé, ó kọ́ wa láti máa kó ẹnu wa ní ìjánu
- Ṣo mọ̀ pé J.F Odunjo jẹ aṣòfin àti mínísítà nílẹ̀ yìí, yàtọ̀ sí pé ó jẹ́ òǹkọ̀wé?
- Ó pé ọdún mẹ́rìnlélàádọ̀ta tí Akintola kú, ìdí abájọ ìja rẹ̀ pẹ̀lú Awolowo rè é
Ẹnu onikan la ti n gbọ kanun, ẹ gbọ ọrọ latẹnu ọkunrin yii funra yin.