Kayode Olabode killed in Ondo : Opó àti àbúrò olóògbé ní ikú Kayode Olabode kìí ṣe àtọ̀runwá
Kayode Olabode killed in Ondo : Opó àti àbúrò olóògbé ní ikú Kayode Olabode kìí ṣe àtọ̀runwá
Ọkunrin kan nilu Akure, Kayode Olabode, ni wọn ni ọlọpa mẹta kọlu, to si sagbako iku ojiji lati ipasẹ sọbiri ti wọn fi gba lori.
Gẹgẹ bi opo oloogbe. Olayinka Olabode ati aburo oloogbe, Olugbenga Agbebi ti salaye fun BBC Yoruba, wọn ni awọn ọlọpaa naa fẹ gba ilẹ ọhun fun ara wọn ni, ti wọn si salaye awọn ohun to mu ifura lọwọ nipa iku oloogbe naa ati bi ejo se lọwọ ninu.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Mọrèmi Àjàṣorò, akọni obìnrin tó gba Ilé Ifẹ̀ sílẹ̀ lóko ẹrú
- Ọ̀rọ̀ǹpọ̀tọ̀niyùn, Aláàfin obìnrin àkọ́kọ́ rèé, tó ní nǹkan ọkùnrin
- Baṣọ̀run Gáà, tó yan ọba mẹ́rin, pa ọba mẹ́rin àmọ́ ọba karùn-ún ló pa á
- Ọbasanjọ sọ àsírí sàgbàdèwe rẹ̀
- Jesu Oyingbo rèé, pásítọ̀ tó láṣẹ ìbálòpọ̀ lóri ọmọ ìjọ obìnrin
- Igbó mímu lè ṣe kóríyá, kò lé fi kún orín ẹnu òṣèré - 9ice
- Ìtàn tó wà nídi òwe ‘Sebótimọ Ẹlẹ́wà Sàpọ́n’
- Ọba Adesoji Aderemi, Ọọ̀ni Ifẹ̀ tó gba ipò ọba mọ́ tòṣèlú
Amọ ileesẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo ti wa fesi pe aisan ẹjẹ ruru lo mu ẹmi oloogbe naa lọ, iku rẹ ko si wa lati ọwọ ẹnikẹni.
Alukoro fun ileesẹ ọlọpaa Ondo, Tee-Leo Ikoro ni awọn ti tu awọn afurasi to wa ni ahamọ silẹ lẹyin abajade iku Olabode, ti wọn si ri pe iku atọrunwa ni, ko ni ọwọ aye ninu.