Big breast: Damilola Adegboro, Oluwaseun Amoo, Remi Fatolu: Ẹlòmíì ń fi irú ọyàn wa tọrọ
Ariwo ọyàn ńlá ló máa ń tẹ̀lẹ́ mi ní gbogbo 'bus stop'- Damilola Tosin Adegboro
Leyin iforowanilenuwo BBC pẹlu Remi Fatolu, ọpọ obinrin miran to lọyan naa tún ti jáde sita sọrọ soke nipa idẹyẹsi ti oju wọn n ri.


Damilola Oluwatosin Adegboro ati Oluwaseun Amoo jade sita wa sọ idẹyẹsi ti awọn n koju nitori ọyan aya wọn bo ṣe tobi to.
Oluwatosin ni orin Ọlọmurọrọ maa wolẹ ni awọn kan gana an ma n kọ fun oun ni eyi to jẹ orin aalọ apagbe to ṣafihan obinrin to lọyan.
- Àwọn àgbà wo ló fọ́wọ́ ọlá gbá gbajúgbajà òṣèré Jamiu Afeez lójú tó ń wa ẹkún mu lóríi sinimá tó ṣe?
- A kú oríire! Oró agbọ́n leè wo àìsàn jẹjẹrẹ ọmú sàn, wo ohun tí wàá lò pọ̀ mọ́ra wọn
- Ẹ̀yin adarí Nàíjíríà, ₦15bn tẹ́ ń ná lọ́dún fún ìlera lókè òkun ti pọ̀jù - Dókítà l‘Amẹ́ríkà
- 'Àti kékeré ni mo ti ń tẹ̀lé bàbáa mi lọ ibi iṣẹ́ tórí mo fẹ́ mọ iṣẹ́ Mọkálìíkì'
- Wasiu Ayinde ti ẹrọ̀fọ̀ dé ibi gíga, bí ikú bàbá rẹ̀ tiẹ̀ ṣèdíwọ́ láti lọ sílé ẹ̀kọ́
- Àmúlò ẹ̀rọ POS fun òwò ṣíṣe, ṣé ó tọ̀nà nínú Islam àbí bẹ́ẹ̀ kọ́?
Remi Fatolu ni inu oun dun pe oun ṣe ifọrọwanilẹnuwo naa pelu BBC nitori pe nkan yi pada pẹlu oju ti awọn eeyan fi n wo oun ni awujọ.Remilekun Fatolu bú sẹ́kún fún ohun tó ti pàdánù láyé torí ọyàn ńla rẹ̀.
Tosin Adegboro ni oju onidọti ni ọpọ ọkunrin fi n wo awọn to lọyan, ṣugbọn irọ ni eyi.

Ọpọ ọkunrin lo wu lati maa fẹ awa ti a ni ọyan nla ṣugbọn wọn ko fẹ gbe wa silẹ bii iyawo- Oluwatosin Adegboro.
Awọn obinrin miran maa n bẹbé pe ki n fun awọn ni diẹ lara ọyan mi ni, ọyan naa ti su mi.
Wọn mẹnuba awọn ipenija ti wọn n ri lawujọ ati eebu lọdọ awọn obinrin miran lori ọyan nla wọn.
Tosin ni ọpọ igba ni oju maa n ti oun nitori ọyan nla naa.

Mi ò kí ń fẹ́ ya fọ́tò tabi ki n jade kuro nile nitori eèbú nipa ọyan nla ti mo ni- Tosin Adegboro
Ọpọ maa n jẹ ko dabi pe iwọ lo da ara ẹ pẹlu ọyan nla tabi ohun to wu eeyan ni.
Remi Fatolu gab awọn obinrin to ni ipenija yii nimọran lati jade sita sórọ ki wọn si gab kadara ki ara wọn le fuyẹ.

Oluwaseun Amoo ni ki awọn eeyna dẹkun idẹyẹsi obinrin to ba ni ọyan nla nitori pe ko rọrun rara.
Oluwatosin Adegboro ni ko wu ẹni to ni ọyan nla naa bẹẹ nitori pe oun kọ lo da ara rẹ ati pe ọrọ awọn eeyan maa n fa ironu ati ibanujẹ ti eeyan ko ba ṣọra.
- Ṣé lọ́ọ̀tọ̀ ní àkúdááyà wà? ẹ̀ wo ìrírí àwọn tó rí ènìyàn wọn tó kú láàyè
- Ẹ yé ṣí ìhòhò ara yín síta lórí ayélujára torí ‘Silhouette Challenge’ - Adeboye
- Òfin kónílé-ó-gbélé gbòde nílùú Igangan lórí ẹ̀rù pé Fulani le k'ógun wá lẹ́yìn àbẹ̀wò Igboho
- Èèyàn mẹ́tàdínlógún(17) jọ́ná ráúráú nínú ìjàmbá ọkọ̀ bọ́ọ̀sì lópòpóónà Bode-Saadu sí Jebba
- Wo bí o ṣe lè di ọmọ onílùú ní Dubai pẹ̀lú òfin tuntun orílẹ́èdè U.A.E.