Buhari on Zamfara: Buhari ni káwọn agbófinró ó yìnbọn fáwọn tó ń gbé ìbọn AK-47, àwọn ọmọ Nàìjíríà ń pariwo "lórí irọ́"

Oríṣun àwòrán, Tweeter/@MBuhari
Aarẹ Muhammadu Buhari ti paṣẹ pe ki awọn agbofinro o maa yinbọn si ẹnikẹni ti wsn ba ba ibọn atamatase AK-47 lọwọ rẹ.
Eyi wa lara awọn igbesẹ tuntun ti aarẹ orilẹede Naijiria, Muhammadu Buhari n gbe lati dẹkun gbọnmọgbọnmọ iwa ijinigbe, ati ikogunjalu to n waye loirlẹede Naijiria.
- Àwọn ará abúlé kan ṣàwàrì àlùmọ́ọ́nì gòólù ní wọ́n bá kígbe síta ní Ọlọ̀pàá bá yi wọn ká!
- Àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Sadiq Daba 'Inspector Waziri' nínú sinimá October 1 tó jáde láyé rèé
- Baba tó dàbí MC Oluomo láyé yìí kò sí, ẹni tó bá níi, ó ní ohun gbogbo- Ọmọ MC Oluọmọ
- Báwo ní Ọba Rilwan Akiolu tí ìlú Eko ṣe ní $2 million àti N17 million sí inú àfin rẹ̀?
Agbẹnusọ fun aarẹ, Garba Shehu ni ijọba apapọ ti wa gba bayii lati fi irin koju irin lori wahala to n fojojums gogo bayii lawọn ipinlẹ bii Zamfara atawọn ipinlẹ miran lẹkun ariwa orilẹede Naijiria.
"Aarẹ ti pasẹ fawọn agbofinro lati wọ gbogbo awọn igbo to jẹ ibuba awọn oniṣẹ ibi naa lọ ki wọn si le wọn jade, ki wọn si doju ibọn kọ ẹnikẹni ti wọn ba ri nibẹ pẹlu awọn ohun ija oloro bii AK-47".
Francis Olusola Alao: Wọ́n ti ti ọ̀rọ̀ òṣèlú bọ ọ̀rs Sunday Igboho, ṣùgbọ́n..- Oba Olugbọn
Shehu Garba tun jẹ ko di mimọ pe idi ti aarẹ Buhari fi paṣẹ pe ko gbọdọ si baluu kan ti yoo tun fo mọ nipinlẹ Zamfara.
O ni eyi ko ṣẹyin lẹyin iwadii awọn ọtẹlẹmuyẹ to fihan pe awọn baluu aladani kan n fo wọ ipinlẹ naa lati ko nnkan ijagun oloro fawọn apanilẹkunjaye naa.
Sugbọn awọn ọmọ Naijiria ti n fi ero wọn han lori eyi ti ero wọn si ṣe ọtọọtọ lori rẹ.
Oríṣun àwòrán, facebook/screenshot
Fulani-Yoruba Crisis: Oba Soun ló fí mi jẹ ọba Sabo ni Ogbomọṣọ- Alh Haruna Bala Abdulsala
Bi awọn kan ṣe n bi aarẹ leere boya o ti ṣeto awọn ohun ija to lee koju eyi tawọn sbayejẹ yii n ko dani, fawọn agbofinro lawsn miran n pariwo pe ileri bẹẹ kii n fi ẹsẹ mulẹ.
- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn tó ń ṣe ayédèrú abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19
- Wòlíì Kasali gba Bunmi ìyàwó rẹ̀ àkọ́fẹ́ padà, ìjà parí!
- Wọ́n ti tú akọ̀ròyìn BBC, Girmay Gebru sílẹ̀ kúrò látìmọ́lé ní Tigray
- "Sọ́jà fi ìbọn gé mi lọ́wọ́ kó lè fipá bámi lòpọ̀"
- Ọjà oùnjẹ ti ń wọ ilẹ̀ Yorùbá àti Igbo láti ilẹ̀ Hausa báyìí- Alhaji Aminu
Ninu ọrọ tirẹ loju opo BBC News Yoruba ni facebook,
Oríṣun àwòrán, Screenshot/facebook
- Ọlọrun má jẹ́ kí a jẹ́ gbèsè lókù báyìí tí a kò kó ọjá lọ sílẹ̀ Yorùbá mọ́- Hausa Oníṣòwò
- Nǹkan dé, Igboho ní káwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Yorùbá lọ múra ògùn jọ nítorí ohun tó ń bọ̀ lọ́nà
- Ewú ńbẹ! tí ìjọba ìpínlẹ̀ bá sàkóso gbèndéke owó oṣù òṣìṣẹ́,wọ́n ò ní san N30,000, N10,000 ní wọ́n má á san -NLC
- Àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́bìnrin gbé ní Zamfara fẹ́ yẹ̀yẹ́ Ìjọba Buhari ni- Hadi Sirika
- Wo ibi tí o ti lè fi orúkọ síìmù rẹ sílẹ̀ tàbí gba nọ́mbà tuntun tí síìmù rẹ bá sọnù
Olusegun Obasanjo: Ọmú ìyá mi ti mo fi ń mùkọ ni kekere ló jẹ ki ń lókun