Fire accident victim: AbdulQudus Bello ṣàlàyé bí òun ṣe dí aláàbọ̀ ara nítorí pọpọ́ọ̀fù àti ìbínú jàǹdùkù àdúgbò
Fidio yii ni awọn aworan to le bani lẹru
Mi o wọ ẹwu ati bata ti mo fi de ile iwosan nigba ti mo gbọ- Iya Qudus
Ni Ilọrin ni iṣẹlẹ yii ti ṣẹlẹ nibi ti Abdul Qudus to n ta pọpọọfu loju titi ti kagbako lọjọ naa.
- Sanwo-Olu buwọ́lu ìgbésẹ̀ ìjọba láti tún Eko ṣe lẹ́yìn rògbòdìyàn EndSARS
- Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀
- A kó ní sanwó oṣú ASUU láìjẹ́ pé wọ́n gba IPPIS- Ìjọba Àpapọ̀
- Banki Nàìjíríà, CBN ṣàlàyé nípa àwọn tó máa rí gbà nínú owó ìrànwọ́ N75b tíjọba gbé kalẹ̀
- Ìdájọ́ ikú ló bá dé fáwọn méjì tó fipá bá ọmọ ọdún mẹ́rìnlá lò pọ̀
O ni awọn janduku ati agbero maa n wa gbowo ita lọwọ awọn to n taja ati pe nigba mii wọn ko ni gba owo, wọn a fi gba pọpọọfu.
Abdulkareem Bello to jẹ iya Qudus ni oun ko wọ nkankan ti oun fi sa de ile iwosan General ti wọn gbe ọmọ oun lọ.
- Ṣé ẹ̀yin ti rí ọkùnrin tó ń sún ẹ̀kún ìyàwó rí?
- Bí àwọn kan tí ń ní àtimọ̀lé tí wọ́n sọ olorin Nazir sí ní Kano ni ọwọ́ kan òṣèlù ní àwọn mii ní...
- Ẹkún àti ìbànújẹ́ láwọn mọ̀lẹ́bí fi sìnkú ọmọ méje ní Kumba, Cameroon lónìí
- Wo bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe n kí fún ìjọba nítorí $1.2bn Naira tó fẹ́ ẹ yá lọ́wọ́ Brazil
Alaba lati ile Salamaleku ni Ilorin ni wọn ni o fi ibinu da ororo gbigbona si Qudus nigba ti iyẹn ko tete fun un ni pọpọọfu oni igba naira to n beere fun.
Qudus royin ohun ti oju rẹ ri to nile iwosan ko to gbadun de ibi to de yii.
Bayii Alaba ile Salamaleku to da ororo lu Qudus ti wa ni atimọle ọlọpaa ni Ilorin ni ipinlẹ Kwara ni guusu Iwo oorun Naijiria.
Idajọ ododo ati iranlọwọ ni ẹbi Qudus n beere fun bayii.
- Afẹ́fẹ́ gáàsì tí gbiná ní Ijora ìpínlẹ̀ Eko, bó ṣe n ṣẹlẹ̀ rèé
- Oyinkan Abayomi, akọni obìnrin tó fi ìfẹ́ pa orúkọ ọkọ kejì dà sí ti ọkọ àárọ̀
- A ti gbé ìwádìí dìde lórí ìpànìyàn tó wáyé lásìkò ìwọ́de EndSARS- Ilé ẹjọ́ àgbáyé, ICC
- Sunny Ade (KSA) máa ń bá Orlando Owoh kó "Gloves" tó fi ń ja ẹ̀ṣẹ́ dání nígbà ayé rẹ̀- Folarin, àbúrò Orlando Owoh