Mike Tyson vs Roy Jones: Ìjà Mike Tyson pẹ̀lú Roy Jones Jr kò ní wáyé mọ́ lóṣù tó ń bọ̀- The Ring

Oríṣun àwòrán, Instagram/miketyson
Ija laarin abẹṣẹ ku bi ojo to ti fẹyin ti, Mike Tyson ati Roy Jones ti di siso rọ bayii.
Ọjọ kẹjọ, oṣu kẹsan an, ọdun 2020 yii lo yẹ ki ija naa waye tẹlẹ, ṣugbọn ọjọ kejidinlọgbọn, oṣu kọkanla ni ija ọhun yoo waye bayii.
Ileeṣẹ The Ring sọ ninu iroyin kan to gbe jade pe awọn onigbọwọ sun ija naa siwaju lati le fi ija naa pa owo daadaa.
- Lampard laná! Arsenal fa Chelsea ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ gba ife FA Cup
- Mama Arsenal ṣeé débi èrè, ẹgbẹ́ kan ti fún màmá l'ẹ̀bùn owó
- Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà
- Buruji Kashamu jẹ́ ènìyàn tó nífẹ̀ aráàlú- Gómínà Dapo Abiodun
- Baba Obasanjọ kò ní àrùn Coronavirus- NCDC
Igba akọkọ ree ti gbajugbaja abẹṣẹ ku bi ojo, Tyson yoo maa lewọ ninu ẹṣẹ kikan lẹyin to ti fẹyinti ni bii ọdun mẹẹdogun sẹyin.
Ni Carson ni California ni ija naa yoo ti ṣẹlẹ.
Adari ajọ to n ri si ere idaraya nipinlẹ California, Andy Foster ti sọ tẹlẹ pe ija laarin Tyson ẹni ọdun mẹtalalaadọta ati Jones, ẹni ọdun mọkanlelaadọta da bii eremọde tabi igbaradi fun ija.
- Kí ló mú Obasanjo ti ilẹ̀kùn mọ́ ẹbí, òṣìṣẹ́, ojúlùmọ̀ ní ibi òkú àna rẹ̀?
- Funke Akindele fún mi lówó tí mo fi gba ilé, kò ra ilé fún mi o - Ajirebi
- Mínísítà fún ọ̀dọ́ àti eré ìdárayá tí fi ẹ̀bùn owó ránṣẹ́ si ìyá Kausara, ó tún jẹ́jẹ̀ẹ́ ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ f'áwọn ọmọ rẹ̀
- Ènìyàn tó tó igba ló ti bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìbúgbàmù tó wáyé ni Lebanon rin báyiìí
- Olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún ọ̀rọ̀ ibojì òkú, àti àwọn ipò òṣèlú mìíràn tó jẹ́ kàyééfì ní Nàìjíríà
Ṣugbọn Jones sọ pe oun ṣetan lati na tan bi powo pelu Tyson nitori oun ko wo ija gẹgẹ bi eremọde rara.
Ọdun 2005 ni Tyson ja kẹyin nigba ti Kevin McBride lu u lalubami.
Oríṣun àwòrán, Instagram/miketyson
Ọdun 2018 ni alatako rẹ, Jones kẹyin, oun lo si bori alatako rẹ, Scott Sigmon lọdun naa.
- Diezani gan an ní Hushmummy tó ń bú àwọn Yahoo boys- Àwọn Ọmọ Naijiria lórí Twitter
- A ti bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí ibì tí owó tí àwọn adigunjalẹ̀ gbé ní banki Okeho wọ̀lẹ̀ sí- Ọlọ́pàá
- Awuyewuye ń wáyé lórí bí ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna ṣe kó àwọn oníbárà sí àhámọ́
- Ìyàwó Bukola Saraki fún tìyá-tọmọ olójú búlúù ní N250, 000!
- Mo ti buwọ́lu àdínkù owó orí nítorí ìrọ̀rùn àwọn èèyàn ìpínlẹ̀ Ogun lásìkò Covid 19- Dapo Abiodun
BBC Africa Eye: ìwádìí ìkọ̀ks BBC fihàn pé àwọn kan ń jí ohun èèlò ìdáàbòbò ìjọba tà nígbo