South Africa: Oyún inú nínú ilé ìgbọ̀nsẹ ọkọ̀ bàálú tó fẹ rinrin àjò

Ó jọ bi ẹ ni pe ẹni kan to ni oyún ti kò fẹ ọmọ ti yọ oyun ọmọ náà si inú ilé ìgbẹ́ inú ọkọ òfurufú.
Ní orílẹ̀-èdè South Africa ni ọkọ̀ òfurufú tó n lọ lati ìlú Durban si Johannesburg ti di ilé igbẹbi fún ikoko kan.
Lojiji ní ọkan lára àwọn tó ń tójú àyíka ke gbàjare lẹ́yìn to lọ toju ọkọ̀ bàálu ti yóò rin ìrìn ajo ọhun.
- Wo àwọn ẹranko tí wọ́n máa figagbaga ni Egypt
- Super Falcons gòkè odò bọ́ sípele ìkẹrìndínlógún ní France
- Oko òkú rèé, níbití òkú ti ń jẹrà mọ́lẹ̀ fún àyẹ̀wò
- Buhari gb'alejo asoju orilẹede South Africa

Alaṣẹ Ọkọ̀ ofúrúfu Fly Safari sọ nínú àtẹjade rẹ lori ẹrọ alátagbà wọn pé inu ilé igbẹ ni wọ́n ti ri ẹjẹ ọrun tuntun ọ̀hun, èyí to si nílò ìwádìí nílànà òfin.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ní ó jọ bi ẹni pé ẹnikan ń gbìyànjú láti ma jẹ ki ẹnikẹni mọ pé òún bímọ.
Agbenusọ fawọn agbofinro ni South Africa, Thembeka Mbele ni ọrọ naa jọni lọju gidi ṣugbọn iṣẹ iwadii ṣi n lọ.
- Kíló fa ìpànìyàn tó tún ń wáyé ní South Africa
- South Africa: Wọ́n jó ọmọ Nàíjììrà nína láàyè
- Ẹgbẹ̀rún kan dín máàrún awakusa bọ lọwọ iku ni South Africa
- 'Ọgbun to wa niwaju aarẹ tuntun ni S/Africa'
Ìròyìn sọ pé ọkọ ofurufu náà ti balẹ̀ sí Durban láti alẹ ọjọbọ lẹ́yìn to tààjò dé láti Johannesburg.
- Iṣẹ́ bọ́ lọ́wọ́ ọ̀gá ilé iṣẹ́ tó bẹ́nu àtẹ̀ lu Obinrin
- Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ Burundi
- Lẹ́yìn ò rẹyìn Seyi Makinde búra fún ìgbìmọ̀ olùgbaninímọ̀ràn
- Bí eṣinṣin bá kọ́já, wíwọ́n ní, lásìkò ìṣíde AFCON 2019
