Nigerian Association of Resident Doctors: Ìyanṣẹ́lódí aláìlójọ́ bẹ̀rẹ̀ káàkiri Naijiria ní

Igba kẹrin ni yii ninu ọdun 2021 ti awọn dokita lorilẹede Naijiria kaakiri gunlẹ iyanṣelodi lati bere fun afikun owo oṣu wọn ni ọwọ ijba.
Awọn dokita to ba BBC sọrọ ni ijọba kuna lati risi eto igbaye gbadun awọn dokita ati ẹkọ to peye fun wọn.
Awọn dokita naa ni aibikita ijọba si ilakọja awọn dokita kaakiri n fa ifaṣẹyin fun eto ilera ni Naijiria.
- Olaiya Igwe ò kú o, àyè ló wà
- Àwọn ọmọ Sunday Igboho mẹ́jọ̀ nínú méjìlá níkan ní DSS gbé wá sí iléẹ̀jọ́ - Agbẹjọrò
- Ìgbìmọ̀ ẹlẹ́nu mẹ́rin ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ lórí ọ̀rọ̀ ìwádìí Abba Kyari àti Ramoni Igbalode
- Micheal kó sí gbaga ọlọ́pàá lórí ẹ̀sùn pé ó lu ọlọ́kadà pa ní Abeokuta
- Rògbòdìyàn yóò bẹ́ sílẹ̀ láàrin Naijiria àti Benin tí wọ́n bá fi Sunday Igboho sílẹ̀ báyìí- Agbẹjọ́rò
- Fúnrara Bukola Saraki ló lọ sí EFCC láti lọ yanjú ọ̀rọ̀ ara rẹ̀- Agbẹnusọ Saraki
Wọn ni ijọba kọ lati mu adehun ti wọn ṣe pẹlu wọn ṣe ni nkan bi osu mẹrin ṣẹyin ti wọn da wọ iyanṣelọdi duro nigba naa.
Kaakiri Naijiria, awọn dokita akẹkọmọṣẹ, Resident doctors lo poju ninu awọn dokita to n ṣiṣẹ ni Naijiria.
Ni ọpọ igba ni iyanṣelodi wọn ma n ni ipalara fun awn to nilo dokita, ti gbogbo ileewosan yoo si da paro-paro.
Esabod, Sunday Igboho: Kò burú bí Igboho ṣe wà lẹ́wọ̀n báyìí,ọ̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i ti aláboyún
Ìdí rè é tí a ó fi gùnlẹ̀ ìyanṣẹ́lódí aláìlójọ́ káàkiri Naijiria - Ẹgbẹ́ Dokítà
Ẹgbẹ awọn Dokita lorilẹede Naijiria, NARD ti sọ wi pe awọn yoo bẹrẹ iyanṣẹlodi kaakiri orilẹede Naijiria bẹrẹ lati Ọjọ Aje, Ọjọ Keji, Oṣu Kẹjọ, 2021.
Aarẹ ẹgbẹ NARD, Dr. Okhuaihesuyi Uyilawa, lo kede rẹ ni ilu Umuahia to jẹ olu-ilu Abia lẹyin ipade gbogbo awọn igbimọ alakoso ẹgbẹ naa.
Dokita Uyilawa ninu ọrọ rẹ sọ idi ti awọn yoo fi gunle iyanṣelodi ọlọjọ gbọọrọ naa nitori ijọba apapọ kọ lati mu gbogbo ileri wọn ṣe.
- "Tinubu ò kú o, àlááfíà ló wà, àmọ́..."
- Bukola Saraki ti wà ní àhámọ́ àjọ EFCC
- Wo ohun mẹ́wàá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Rachel Oniga tó d'ágbére f'áyé
- Ọ̀gá Àgbà Ọlọ́pàá, ẹ ríi dájú pé ẹ tú gbogbo àṣírí nípa ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan Abba Kyari àti Hushpuppi - Àpapọ̀ Agbẹjọ́rọ̀
- Èyí ni àlàyé lórí ètò ìsìnkú Tope AjogbaJesu àti ọjọ́ tí wọn yóò sin ín
- 'Hàá, irú ikú tí ọmọ mí kú kò tọ́ síi, aláànú mí ní'
O ni lati ọdun mẹwa ṣẹyin ni ẹgbẹ awọn dokita ti ni adehun pẹlu ijọba apapọ lori ọna ati mu idagbasoke ba eto ilera ni Naijiria, ti wọn ko si ri nkankan ṣe si titi di asiko yii.
Lara awọn idi ti wọn fi fẹ gunle iyanṣelodi naa re e;
- Aisi agbegbe ati ileewosan to dara fun awọn araalu ati awọn dokita latio ṣiṣẹ
- Aisi san owo osu awọn dokita loore-koore.
- Ijọba apapọ kuna lati ma a san owo ijamba to jẹ ẹgbẹrun marun un to yẹ ki wọn ma a fun awọn dokita ni oṣooṣu lati ọdun 1991.
- Ijọba kuna lati fi wọn si apo isuna ijọba ''personal payroll information systems'', ki owo osu wọn le ma a wọle deede.
Olagunsoye Oyinlola: Kí Olorun dáríjì wá lórí ọ̀rọ̀ yíi, a ti kùnà ìlérí wa fún ìran Yorùb
- Ẹbi kan pere ninu ẹbi mọkandinlogun awọn dokita ti Coronavirus gbẹmi wọn lẹnu iṣẹ nikan lo ti ri owo ifẹyinti fun awọn oloogbe wọn gba.
- Ijọba kọ lati dahun si gbogbo ipenija to n koju ẹka eto ilera lorilẹede Naijiria
Peter Fatomilola kìí ṣe agbódegbà Yahoo, Ó ń fẹ́ kí ìjọba, Òbí àti ilé ìjọsìn ṣe ohun tó y
- Ida mẹrin aba iṣuna Naijiria nikan lo wa fun eto ilera nigba ti ida marundilọgbọn si aadọta lo wa fun owo oṣu awọn oṣelu ni Naijiria.
- Ijọba ipinlẹ Eko yọ awọn ẹkọṣẹ dokita( Interns, Resident doctors) kuro ninu awọn ti ijọba yoo ma san owo oṣu fun un.
Ẹgbẹ awọn dokita ni Naijiria wa rọ tọrọ aforiji lọwọ awọn ọmọ Naijiria ti iyanṣelodi naa yoo fa ipalara fun wọn.
Amọ wọn ni ijọba gbọdọ mu ileri wọn ṣe lori gbogbo adehun ti wọn ṣe pẹlu ẹgbẹ awọn dokita kaakiri orilẹede Naijiria.
- Àfìgbà tóò dúró ká jọ gbé orin tuntun wa pẹ̀lú Alhaji Mustapha Abiola jáde - Ẹnìkejì Tope Ajogbajesu
- Ìrètí Nàìjíríà bọ́ sómi! Ògùn olóró líló mú kí AIU lé Blessing Okagbare kúrò ní Tokyo 2020 Olympics
- Ikú Tope AjogbaJesu, ohun tí a mọ̀ nípa ohun tó ṣokùnfà ikú rẹ̀ nìyí
- 'Lábẹ́ òfin àjọ ECOWAS, kó ṣééṣe kí Benin Republic jọ́wọ́ Sunday Igboho fún Nàìjíríà'
- Àwọn ohun mẹ́rin tó yẹ kí ẹ ko mọ nípa Ramoni Igbalode tí gbogbo ayé ń pè ní Hushpuppi
- 'Nàiìjíríà ti pèsè ''Private jet'' tí yóò gbé Igboho padà sílé láti Cotonou sílẹ̀ kí ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ tó bẹ̀rẹ̀'