Tí a fiṣọwọ́ ní 14:23 3 Ẹrẹ̀nà 202114:23 3 Ẹrẹ̀nà 2021Wo ohun tí Ńo-Fly Zone' túmọ̀ síAàrẹ Buhari kéde pé ọkọ̀ òfurufú kankan kò gbọdọ̀ fò ní Zamfara mọ́ nítorí ètò aàbò.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 7:29 28 Èrèlè 20217:29 28 Èrèlè 2021Àwọn jàndùkú ajínigbé fẹ́ẹ̀ lù wá pa nínú igbó, ọ̀rọ̀ rèé lẹ́nu àwọn àkẹ́kọ̀ọ́ ìlú KagaraGomina ipinlẹ Niger sọ pe gbogbo eeyan mejidinlogoji ti wọn jigbe ni wọn ti gba itọju nile iwosan.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 6:11 28 Èrèlè 20216:11 28 Èrèlè 2021Ẹ wo ohun tí a mọ̀ nípa Dawisu tí gómínà Kano yọ ní íṣẹ́ nítorí o sọ̀rọ̀ tako Ààrẹ BuhariSalihu Tanko Yakasai ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Dawisu lórí Twitter ni olùbádámọ̀ràn pàtàkì lórí ètò ìròyìn sí gómìnà ìpínlẹ̀ Kano.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:19 24 Èrèlè 202113:19 24 Èrèlè 2021Fayemi: Àfàìmọ̀ kí ìjọba má bá àwọn jàndùkù ajínigbé sọ̀rọ̀, àmọ́ onímọ̀ nípa ètò àbò ní ...Gomina ipinlẹ Ekiti, Kayode Fayemi sọ pe biba awọn janduku agbebọn yii sọrọ wa lara awọn ọna lati wa ojutu si iṣoro eto abo.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:38 23 Èrèlè 20215:38 23 Èrèlè 2021Àwọn jàndùkú ajínigbé kìí sáábà sekú pààyàn, owó ni wọ́n ń fẹ́- Sheikh GumiSheikh Ahmad Gumi ni awọn ajinigbe ṣetan lati gbe ibọn wọn silẹ ti ijọba ba le ni ifọrọwerọ pẹlu wọn.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:38 21 Èrèlè 20219:38 21 Èrèlè 2021Àwọn olóṣèlú gbọdọ̀ máa fi Ògún búra, bí Nàìjíríà bá fẹ́ dẹ́kun ìwà àjẹbánu - Guru Maharaj jiGuru Maharaj ji sọrọ yii nibi apero kan to da lori awọn iṣẹlẹ to n ṣakoba fun gbogbo agbaye bayii lọjọ Abamẹta.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:37 21 Èrèlè 20215:37 21 Èrèlè 2021Ìjọba sọ̀rọ̀ lórí ìròyin tó ní Benin Republic fẹ́ di ìpínlẹ̀ kẹtàdínlógójì ní NàìjíríàNiṣe lori ayelujara gbona giri giri lẹyin ti ọgọọrọ eeyan n gba ọrọ naa bi ẹni n gba igba ọti lori Twitter ati Facebook lọjọ Satide.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:30 20 Èrèlè 202110:30 20 Èrèlè 2021Fáàbàdà! Ìjọba ò sanwó fáwọn ajínigbé láti fi àwọn akẹ́kọ̀ọ́ iléèwé Kagara sílẹ̀- Lai MohammedMinisita eto iroyin ati aṣa, Lai Mohammed lo sọrọ lori ileeṣẹ ẹrọ amohunmaworan Channels.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 15:01 18 Èrèlè 202115:01 18 Èrèlè 2021Ìjọba Naijiria ti kùnà lórí ojúṣe rẹ̀ lóri ètò aàbò- Bode GeorgeOloye Bode George ti ba awọn akọrọyin sọrọ lori bi eto abo Naijiria ṣe n lọ.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:24 18 Èrèlè 202113:24 18 Èrèlè 2021Alhaja Muslimot Salami tí àwọn darandaran kọlù ní Ogun tí padà jẹ́ Olorun nípè!Bukola Saraki fi ewe ọmọ mọ Buhari leti pe bo ṣe dakẹ lori aabo to mẹhẹ, ko le mu ki orilẹede yii rọgbọ.Kà Síwájú Síinext