Tí a fiṣọwọ́ ní 9:06 13 Bélú 20199:06 13 Bélú 2019Àbádòfin ìdájọ́ yíyẹ igi fún 'ni tórí ọ̀rọ̀ ìkóríra! Àwọn ọmọ Nàìjíríà la ohùnÀwọn ọmọ Nàìjíríà ti ń fi èròngbà wọn léde lórì àbádòfin èyí tó ń gbèrò láti fìyà jẹ ẹnikẹ́ni tó bá sọ̀rọ̀ ìkóríra.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 12:15 7 Bélú 201912:15 7 Bélú 2019A gbọ́dọ̀ ṣewàdìí ìròyìn ayélujára kí a tó pin in- OloriSuperGalAgbẹjọ́rò àgbà kan ti sọ pé ìgbésẹ̀ ìjọba àpapọ̀ lórí pínpín ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ kiri lórí ìtàkùn ayélujúra kò burú.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 18:37 31 Ọ̀wàrà 201918:37 31 Ọ̀wàrà 2019Soyombo yẹ fún àyẹ́sí gẹ́gẹ́ bí ògbóǹtagì oníròyìn - AregbesolaMínísítà tó ń rí sí ọ̀rọ̀ abẹ́nú, Rauf Aregbesola ní ohun tó yẹ níí yẹni bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ṣì ń retí àbájádé ìwádìí.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 15:04 1 Ọ̀wàrà 201915:04 1 Ọ̀wàrà 2019Ilẹ China ń sàmì àádọrin ọdun tí wọn gbòmìnira pẹ̀lú ìfẹ̀hònúhànỌ̀pọ̀ ọ̀dọ́ orílẹ̀-ede China ni inu wọn kò dùn sí àyájọ́ òmìnira tónìí pàápàá bí ìbọn ṣe ba Akọròyìn kan.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:33 30 Owewe 20199:33 30 Owewe 2019Kíni àwọn ìpèníjà ẹtọ ààbò ṣáájú òmìnira Nàìjíríà?Ogagun-fẹyinti Sadiq Garba Shehu, ogbontarigi onimọ ninu eto aabo sọrọ lori ohun tó kóju Naijiria nigba ominira ní 1960Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 4:38 30 Owewe 20194:38 30 Owewe 2019Ọmọ Uganda gba àmi ẹ̀yẹ Komla Dumor BBC tọdun yiiAkọ̀ròyìn ọmọ ilẹ̀ Uganda, Solomon Serwanjja ni ó jáwé olúborí tọdún yìí fún àmì ẹ̀yẹ BBC World News Komla Dumor.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 9:52 14 Owewe 20199:52 14 Owewe 2019"Ọ̀pọ̀ àwàdà tí wọn fi ń ‘ṣun èmi àti Buhari lááyè’ lórí ayélujára ló jẹ́ iṣẹ́ ọpọlọ gidi"Amọ sa, Yemi Osinbajo ni oun nigbagbọ ninu ominira fawọn akọroyin, boya awọn to mọ isẹ wọn nisẹ ni abi awọn to n fi isẹ wọn jataa.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 17:58 19 Òkùdu 201917:58 19 Òkùdu 2019A kò fẹ́ Festus Adedayo ní ìjọba Buhari - Àwọn olólùfẹ́ APC yaríOri ẹrọ ikansiraẹni Twitter n gbona níbi tí awọn ọmọ Naijiria ti ni ijọba ko gbọdọ fun Festus Adedayo ni ipo kankan.Kà Síwájú Síinext