Tí a fiṣọwọ́ ní 12:01 18 Ìgbé 202112:01 18 Ìgbé 2021Ṣé lóòtọ́ọ́ ni Makinde pàṣẹ pé kí wọ́n wó iléègbé àwọn òṣìṣẹ́ BCOS ní Ibadan?Ko si ẹni to le sọ pato ohun ti ijọba fẹ fi ilẹ naa ṣe ti wọn ba wo ile to wa lori rẹ tan.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 7:40 18 Ìgbé 20217:40 18 Ìgbé 2021Àwọn tó ń polongo Oduduwa Nation fẹ́ ba àláàfíà, ìfẹ́ àti ìṣọ̀kan ilẹ̀ Yorùbá jẹ́ ni- YWGẸgbẹ to wa fun igbaye-gbadun ilẹ Yoruba, Yoruba Welfare Group sọ pe ọbayejẹ ni awọn to n kede Oduduwa Nation.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:25 17 Ìgbé 20215:25 17 Ìgbé 2021Èmi kọ́ ni mò n pín ìrẹsì lókè Ọya lásìkò àwẹ̀ yìí - Bola TinubuTinubu ṣalaye pe oun ri aworan apo irẹsi ti wọn ya oju oun si lara lori ayelujara, ṣugbọn oun kọ lo wa nidi rẹ.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:06 14 Ìgbé 202110:06 14 Ìgbé 2021Òjòóró ló wáyé lásìkò ìbò PDP l‘Osogbo - FayoseNinu ọrọ ti Ayodele Fayose kọ sori Twitter, o ni igbesẹ imupadabọsipo ẹgbẹ PDP ti bẹrẹ.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 11:07 8 Ìgbé 202111:07 8 Ìgbé 2021Ìjọba àpapọ̀ ní ọ̀rọ̀ ò rí bẹ́ẹ̀; LOC Sports Festival l'Edo ní ìdíje náà kò ní tẹ̀síwájú torí àísówólo sọ lalẹ Ọjọru pe igbesẹ lati da idije naa duro waye nibi ipade ti igbimọ LOC ṣe eleyii ti igbakeji gomina ipinlẹ Edo, Philip Shaibu wa nibẹ.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 10:59 8 Ìgbé 202110:59 8 Ìgbé 2021Ṣé àwọn Ọlọ́pàá ṣẹ àwọn ayé ni tí wọ́n tún kọlu Àgọ́ Ọlọ́pàá míì? Wọ́n jí Ọlọ́pàá kan gbéIkọlu mii tun waye si olu ileeṣẹ ọlọpaa miran ni ipinlẹ Imo lẹyin ọjọ kan ti ikọlu akọkọ wayeKà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 6:40 7 Ìgbé 20216:40 7 Ìgbé 2021Àwọn jàndùkú agbébọn pa èèyàn mẹ́jọ, wọ́n tún jí ọ̀pọ̀ gbé lọ ní KadunaKọmiṣọnna ọrọ abo abẹle nipinlẹ Kaduna, Samuel Aruwan ṣalaye pe awọn agbebọn ọhun di oju ọna lẹba abule Kadanye lagbegbe Kajuru.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 5:11 7 Ìgbé 20215:11 7 Ìgbé 2021Tinubu ló lè ṣeé lọ́dún 2023, Pa Fasoranti àti Oba Osemawe Ondo sọ̀rọ̀ sókèPa Reuben Fasoranti ni ''Tinubu koju osunwọn lati tukọ orilẹede Naijiria pẹlu oriṣiiriṣii nkan to ti gbe ṣe lati ẹyin wa.''Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 7:50 5 Ìgbé 20217:50 5 Ìgbé 2021Ọ̀rọ̀ ètò ìlera Nàìjíríà ń bẹ nínú ewu, Buhari ń fọwọ́ ra àwọn agbésùnmọ̀mí lórí - Bakare, KukahPasitọ Tunde Bakare ni oun sọrọ soke tori iru Naijiria yii kọ ni oun ati ààrẹ Muhammadu Buhari pinu lati ni lasiko ti awọn jọ n dije dupo aarẹ lọdun 2011.Kà Síwájú Síinext
Tí a fiṣọwọ́ ní 13:01 31 Ẹrẹ̀nà 202113:01 31 Ẹrẹ̀nà 2021Àwọn tí àkóso ìjọba bọ́ lọ́wọ́ wọn ló ń ti Igboho lẹ́yìn lórí ìdásílẹ̀ Oodua Nation - YWGYWG gba Yorùbá ní ìmọ̀ràn pé, ọ̀nà àbáyọ tó wà ni ki a pada sí ẹsẹ ààrọ́ níbí tí ẹkùn kọ̀ọ̀kan yóò tí má dari ọ̀rọ̀ ajé wọ́n.Kà Síwájú Síinext